1Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ nípa Ninefe. Ìwé ìran Nahumu ará Elkoṣi.
Ìbínú Olúwa sí Ninefe
2Ọlọ́run ń jẹ owú, ó sì ń gbẹ̀san.
Olúwa ń gbẹ̀san, ó sì kún fún ìbínú
Olúwa ń gbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá rẹ̀,
Ìbínú rẹ̀ kò sì yí padà lórí àwọn ọ̀tá rẹ̀
31.3: Isa 10.5-34; Sf 2.12-15.Olúwa lọ́ra láti bínú, ó sì tóbi ní agbára;
Olúwa kì yóò fi àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ sílẹ̀ láìjìyà.
Ọ̀nà rẹ̀ wà nínú afẹ́fẹ́ àti nínú ìjì,
Ìkùùkuu sánmọ̀ sì ni eruku ẹsẹ̀ rẹ̀.
4Ó bá Òkun wí, ó sì mú kí ó gbẹ;
Ó sìsọ gbogbo odò di gbígbẹ.
Baṣani àti Karmeli sì rọ,
Ìtànná Lebanoni sì rẹ̀ sílẹ̀.
5Àwọn òkè ńlá wárìrì níwájú rẹ̀,
àwọn òkè kéékèèkéé sì di yíyọ́,
ilẹ̀ ayé sì jóná níwájú rẹ̀,
àní ayé àti gbogbo àwọn tí ń gbé inú rẹ̀.
6Ta ni ó lé dúró níwájú ìbínú rẹ̀?
Ta ni ó lé faradà gbígbóná ìbínú rẹ̀?
Ìbínú rẹ̀ tú jáde bí iná;
àwọn àpáta sì fọ́ túútúú níwájú rẹ̀.
7Rere ni Olúwa,
òun ni ààbò ní ọjọ́ ìpọ́njú.
Òun sì tọ́jú àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé e,
8Ṣùgbọ́n pẹ̀lú ìkún omi ńlá
ní òun yóò fi ṣe ìparun láti ibẹ̀ dé òpin;
òkùnkùn yóò sì máa lépa àwọn ọ̀tá rẹ̀.
9Kí ni ẹ̀yìn ń gbìmọ̀ lòdì sí Olúwa?
Òun yóò fi òpin sí i,
ìpọ́njú kì yóò wáyé ní ìgbà kejì
10Wọn yóò sì lọ́lù papọ̀ bí ẹ̀gún òṣùṣú
wọn yóò sì mu àmupara nínú ọtí wáìnì wọn
a ó sì run wọn gẹ́gẹ́ bi àgékù koríko gbígbẹ
11Láti ọ̀dọ̀ rẹ, ìwọ Ninefe, ni ẹnìkan ti jáde wá
tí ó ń gbèrò ibi sí Olúwa
ti ó sì ń gbìmọ̀ búburú.
12Báyìí ni Olúwa wí:
“Bí wọ́n tilẹ̀ ni ìfọwọ́sowọ́pọ̀, tí wọ́n sì pọ̀ níye,
Ṣùgbọ́n, báyìí ní a ó ké wọn lulẹ̀,
nígbà tí òun ó bá kọjá.
Bí mo tilẹ̀ ti pọ́n ọ lójú ìwọ Juda, èmi kì yóò pọ́n ọ lójú mọ́.
13Nísinsin yìí ni èmi yóò já àjàgà wọn kúrò ní ọrùn rẹ
èmi yóò já ṣẹkẹ́ṣẹkẹ̀ rẹ dànù.”
14Olúwa ti fi àṣẹ kan lélẹ̀ nítorí tìrẹ Ninefe:
“Ìwọ kì yóò ni irú-ọmọ láti máa jẹ́ orúkọ rẹ mọ́,
Èmi yóò pa ère fínfín àti ère dídà run
tí ó wà nínú tẹmpili àwọn ọlọ́run rẹ.
Èmi yóò wa ibojì rẹ,
nítorí ẹ̀gbin ni ìwọ.”
151.15: Isa 40.9; 52.7; Ap 10.36; Ro 10.15.Wò ó, lórí àwọn òkè,
àwọn ẹsẹ̀ ẹni tí ó mú ìròyìn ayọ̀ wá,
ẹni tí ó ń kéde àlàáfíà,
Ìwọ Juda, pa àṣẹ rẹ tí ó ní ìrònú mọ́,
kí ó sì san àwọn ẹ̀jẹ́ rẹ.
Àwọn ènìyàn búburú kì yóò sì gbóguntì ọ́ mọ́;
wọn yóò sì parun pátápátá.
Herren ska döma Nineve
1Profetia om Nineve. Boken med en syn av Nahum från Elkosh.
2Herren är en svartsjuk, hämnande Gud,
Herren hämnas och är full av vrede.
Herren tar hämnd på sina motståndare
och behåller sin vrede mot sina fiender.
3Herren är sen till vrede
men stor i kraft,
han låter ingen gå ostraffad.
Herrens väg går fram i storm och oväder,
och molnen är dammet efter hans fötter.
4Han tillrättavisar havet,
han låter det torka ut
och floderna sina.
Bashan och Karmel vissnar,
och Libanons blomning tynar bort.
5Bergen skakar inför honom,
och höjderna smälter ner.
Jorden bävar inför honom,
världen och alla som bor där.
6Vem kan bestå inför hans förbittring?
Vem uthärdar hans brinnande vrede?
Hans vrede brinner som en eld,
och klipporna rämnar inför honom.
7Herren är god,
en fästning på nödens dag.
Han tar sig an dem
som tar sin tillflykt till honom.
8Men med en väldig flod
utplånar han Nineves plats.
Han förföljer sina fiender
ända in i mörkret.
9Vad ni än har för tankar mot Herren,
så ska han göra slut på dem.
Nöden ska inte komma två gånger.
10Som hopslingrade törnen
och druckna av vin
ska de brinna upp
som torr halm.1:10 Grundtextens innebörd är osäker.
11Från dig har det gått ut en man
med onda tankar mot Herren,
en ondskans rådgivare.
12Så säger Herren:
”Hur starka och många de än är
så ska de slås ner och förgås.
Jag har plågat dig, Juda,
men ska inte plåga dig mer.
13Nu ska jag bryta sönder det ok han lagt på dig
och slita av dina bojor.”
14Herren har gett en befallning om dig1:14 Syftar på den assyriske kungen.:
”Det ska inte finnas någon efterkommande
som för ditt namn vidare.
Ur ditt gudatempel ska jag förstöra
alla gudabilder, såväl skurna som gjutna,
och jag ska göra i ordning en grav åt dig,
för du är värdelös.”
15Se, över bergen stiger budbäraren fram
med goda nyheter
och förkunnar fred.
Fira dina högtider, Juda,
infria dina löften,
för den onde ska inte mer invadera dig;
han är fullständigt utplånad.