箴言 3 – CCBT & YCB

Chinese Contemporary Bible (Traditional)

箴言 3:1-35

信靠耶和華

1孩子啊,不要忘記我的訓言,

要把我的誡命存在心裡,

2因為這必使你延年益壽,

幸福平安。

3不要讓慈愛和信實離開你,

要把他們繫在你的頸項上,

刻在你的心坎上。

4這樣,你必蒙上帝和世人的喜悅,

享有美譽。

5你要全心信靠耶和華,

不可倚靠自己的悟性。

6凡事都要尋求祂,

祂必指引你走正路。

7不要自以為有智慧,

要敬畏耶和華,遠離惡事。

8這樣可醫治你的身體,

滋潤你的筋骨。

9你要用自己的財富和一切初熟的物產來尊崇耶和華,

10祂必使你五穀滿倉,

榨酒池溢出新釀。

11孩子啊,不可輕視耶和華的管教,

也不可厭煩祂的責備。

12因為耶和華責備祂所愛的人,

就像父親責備他所疼愛的孩子。

13找到智慧、得到悟性的人有福了,

14因為智慧比銀子更有價值,

比金子更有益處,

15比珠寶更珍貴;

你所喜愛的一切都難以相比。

16智慧的右手有長壽,

左手有富貴和尊榮。

17她的路上有福樂,

她的道上有平安。

18對持守智慧的人來說,

智慧是生命樹,

緊握智慧的人必蒙祝福。

19耶和華以智慧奠立大地,

以悟性鋪設諸天;

20祂的知識使深淵裂開,

使天上降下甘霖。

21孩子啊,你要守護智慧和明辨力,

別讓她們離開你的視線。

22她們必給你帶來生命,

作你頸項上華美的裝飾。

23如此,你必步履穩健,不致失足;

24你必安然躺臥,睡得香甜。

25不要怕突來的災禍,

不要怕惡人遭毀滅,

26因為耶和華是你的靠山,

祂使你的腳不陷入網羅。

27倘若有力量行善,

就當幫助有需要的人,不要推託。

28倘若可以幫忙,

就不可對有求於你的鄰人說:

「回去吧,明天再來,我必給你!」

29鄰舍在你附近安分居住,

不可謀害他。

30別人若沒有害你,

不要無故與他相爭。

31不要羡慕殘暴之徒,

也不可步其後塵,

32因為耶和華憎惡邪僻之徒,

喜愛正直的人。

33耶和華咒詛惡人的家,

賜福義人的家。

34耶和華譏笑好譏誚的人,

恩待謙卑的人。

35智者得尊榮,

愚人受羞辱。

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Òwe 3:1-35

Àwọn àǹfààní ọgbọ́n mìíràn

1Ọmọ mi, má ṣe gbàgbé ẹ̀kọ́ mi.

Ṣùgbọ́n pa òfin mi mọ́ sí ọkàn rẹ.

2Nítorí ọjọ́ gígùn, ẹ̀mí gígùn, àti àlàáfíà,

ni wọn yóò fi kùn un fún ọ.

3Má ṣe jẹ́ kí ìfẹ́ àti òtítọ́ ṣíṣe fi ọ́ sílẹ̀ láéláé

so wọ́n mọ́ ọrùn rẹ,

kọ wọ́n sí wàláà àyà rẹ.

43.4: Ro 12.17.Nígbà náà ni ìwọ yóò rí ojúrere àti orúkọ rere

ní ojú Ọlọ́run àti lójú ènìyàn.

5Gbẹ́kẹ̀lé Olúwa pẹ̀lú gbogbo ọkàn rẹ

má ṣe sinmi lé òye ara à rẹ;

6Mọ̀ ọ́n ní gbogbo ọ̀nà rẹ

òun yóò sì máa tọ́ ipa ọ̀nà rẹ.

73.7: Ro 12.16.Má ṣe jẹ́ ọlọ́gbọ́n lójú ara à rẹ

bẹ̀rù Olúwa kí o sì kórìíra ibi.

8Èyí yóò mú ìlera fún ara rẹ

àti okun fún àwọn egungun rẹ.

9Fi ọrọ̀ rẹ bọ̀wọ̀ fún Olúwa,

pẹ̀lú àkọ́so oko rẹ

10Nígbà náà ni àká rẹ yóò kún àkúnya

àgbá rẹ yóò kún àkúnwọ́sílẹ̀ fún wáìnì tuntun.

113.11,12: Hb 12.5,6.Ọmọ mi, má ṣe kẹ́gàn ìbáwí Olúwa

má sì ṣe bínú nígbà tí ó bá ń bá ọ wí,

12Nítorí Olúwa a máa bá àwọn tí ó fẹ́ràn wí

bí baba ti í bá ọmọ tí ó bá nínú dídùn sí wí.

13Ìbùkún ni fún ẹni tí ó ní ìmọ̀,

ẹni tí ó tún ní òye sí i

14Nítorí ó ṣe èrè ju fàdákà lọ

ó sì ní èrè lórí ju wúrà lọ.

15Ó ṣe iyebíye ju iyùn lọ;

kò sí ohunkóhun tí a lè fiwé e nínú ohun gbogbo tí ìwọ fẹ́.

16Ẹ̀mí gígùn ń bẹ ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀;

ní ọwọ́ òsì rẹ sì ni ọrọ̀ àti ọlá.

17Àwọn ọ̀nà rẹ jẹ́ ọ̀nà ìtura,

òpópónà rẹ sì jẹ́ ti àlàáfíà.

18Igi ìyè ni ó jẹ́ fún gbogbo ẹni tí ó bá gbà á;

àwọn tí ó bá sì dìímú yóò rí ìbùkún gbà.

19Nípa ọgbọ́n, Olúwa fi ìpìlẹ̀ ilẹ̀ ayé sọlẹ̀; nípa òye, ó fi àwọn ọ̀run sí ipò wọn;

20Nípa ìmọ̀ rẹ̀ ó pín ibú omi ní yà,

àwọsánmọ̀ sì ń sẹ ìrì.

21Ọmọ mi, pa ọgbọ́n tí ó yè kooro àti ìmòye mọ́,

má jẹ́ kí wọn lọ kúrò ní ibi tí ojú rẹ ti le tó wọn.

22Wọn yóò jẹ́ ìyè fún ọ,

àti ẹ̀ṣọ́ fún ọrùn rẹ.

23Nígbà náà ni ìwọ yóò bá ọ̀nà rẹ lọ ní àìléwu,

ìwọ kì yóò sì kọsẹ̀;

24Nígbà tí ìwọ bá dùbúlẹ̀, ìwọ kì yóò bẹ̀rù,

nígbà tí ìwọ bá dùbúlẹ̀, oorun rẹ yóò jẹ́ oorun ayọ̀.

25Má ṣe bẹ̀rù ìdààmú òjijì,

tàbí ti ìparun tí ó ń dé bá àwọn ènìyàn búburú.

26Nítorí Olúwa yóò jẹ́ ìgbẹ́kẹ̀lé rẹ,

kì yóò sì jẹ́ kí ẹsẹ̀ rẹ bọ́ sínú pàkúté.

27Má ṣe fa ọwọ́ ìre sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ àwọn tí ṣe tìrẹ,

nígbà tí ó bá wà ní ìkápá rẹ láti ṣe ohun kan.

28Má ṣe wí fún aládùúgbò rẹ pé,

“Padà wá nígbà tó ṣe díẹ̀; èmi yóò fi fún ọ ní ọ̀la,”

nígbà tí o ní i pẹ̀lú rẹ nísinsin yìí.

29Má ṣe pète ohun búburú fún aládùúgbò rẹ,

ti o gbé nítòsí rẹ, tí ó sì fọkàn tán ọ.

30Má ṣe fẹ̀sùn kan ènìyàn láìnídìí,

nígbà tí kò ṣe ọ́ ní ibi kankan rárá.

31Má ṣe ṣe ìlara ènìyàn jàgídíjàgan

tàbí kí o yàn láti rìn ní ọ̀nà rẹ̀.

32Nítorí Olúwa kórìíra ènìyàn aláyídáyidà

ṣùgbọ́n a máa fọkàn tán ẹni dídúró ṣinṣin.

33Ègún Olúwa ń bẹ lórí ilé ènìyàn búburú,

ṣùgbọ́n ó bùkún fún ilé olódodo.

343.34: (Gk): Jk 4.6; 1Pt 5.5.Ó fi àwọn ẹlẹ́yà ṣe yẹ̀yẹ́,

ṣùgbọ́n ó fi oore-ọ̀fẹ́ fún onírẹ̀lẹ̀.

35Ọlọ́gbọ́n jogún iyì,

ṣùgbọ́n àwọn aṣiwèrè ni yóò ru ìtìjú wọn.