箴言 4 – CCBT & YCB

Chinese Contemporary Bible (Traditional)

箴言 4:1-27

父親的教誨

1孩子們啊,

你們要聽從父親的教誨,

留心學習,以便領悟,

2因為我給你們的訓誨是美好的,

不可背棄我的教導。

3我年幼時在父親身邊,

是母親唯一的寵兒。

4父親教導我說:

「要牢記我的話,

遵守我的誡命,就必存活。

5你要尋求智慧和悟性,

不要忘記或違背我的吩咐。

6不可離棄智慧,智慧必護佑你;

你要熱愛智慧,智慧必看顧你。

7智慧至上,要尋求智慧,

要不惜一切,求得悟性。

8高舉智慧,她必使你受尊崇;

擁抱智慧,她必使你得尊榮。

9她必為你戴上華冠,

加上榮冕。」

10孩子啊,你要聽從我的教導,

就必延年益壽。

11我已經指示你走智慧之道,

引導你行正確的路。

12你行走,必不受妨礙;

你奔跑,絕不會跌倒。

13你要持守教誨,不要鬆懈;

要守護好,因為那是你的生命。

14不要涉足惡人的道,

不要行走壞人的路;

15要避開,不可踏足,

要繞道而行。

16因為他們不作惡就無法入睡,

不絆倒人就無法安眠;

17他們吃的是邪惡餅,

喝的是殘暴酒。

18義人的道路好像黎明的曙光,

越照越亮,直到大放光明。

19惡人的道路一片幽暗,

他們不知被何物絆倒。

20孩子啊,你要聆聽我的吩咐,

側耳聽我的訓言;

21不要讓它們離開你的視線,

要牢記在心。

22因為得到它們就得到生命,

全身也必康健。

23要一絲不苟地守護你的心,

因為生命之泉從心中湧出。

24不講欺詐之言,

不說荒謬的話。

25眼睛要正視前方,

雙目要向前直看。

26要鋪平腳下的路,

使所行之道穩妥。

27不可偏右偏左,

要遠離惡事。

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Òwe 4:1-27

Ọgbọ́n ni o ga jùlọ

1Tẹ́tí, Ẹ̀yin ọmọ mi, sí ẹ̀kọ́ baba; fetísílẹ̀ kí o sì ní òye sí i

2Mo fún ọ ní ẹ̀kọ́ tí ó yè kooro

Nítorí náà má ṣe kọ ẹ̀kọ́ mi sílẹ̀

3Nígbà tí mo jẹ́ ọ̀dọ́mọkùnrin ní ilé baba à mí,

mo jẹ́ èwe, tí mo sì jẹ́ ọ̀kan ṣoṣo lọ́wọ́ ìyá mi

4Ó kọ́ mi ó sì wí pé

“Jẹ́ kí àyà rẹ kí ó gba ọ̀rọ̀ mi dúró,

pa òfin mi mọ́, kí ìwọ kí ó sì yè.

5Gba ọgbọ́n, gba òye,

Má ṣe gbàgbé ọ̀rọ̀ mi tàbí kí o yẹsẹ̀ kúrò nínú rẹ̀

6Má ṣe kọ ọgbọ́n sílẹ̀, yóò sì dáàbò bò ọ́,

fẹ́ràn rẹ̀, yóò sì bojútó ọ.

7Ọgbọ́n ni ó ga jù; nítorí náà gba ọgbọ́n.

Bí ó tilẹ̀ ná gbogbo ohun tí o ní, gba òye

8Gbé e ga, yóò sì gbé ọ ga

dìrọ̀ mọ́ ọn, yóò sì bu iyì fún ọ.

9Yóò fi òdòdó ọ̀ṣọ́ ẹwà sí orí rẹ

yóò sì fi adé ẹlẹ́wà fún ọ.”

10Tẹ́tí, ọmọ mi, gba ohun tí mo sọ,

Ọjọ́ ayé è rẹ yóò sì gùn.

11Mo tọ́ ọ ṣọ́nà ní ọ̀nà ti ọgbọ́n

mo sì mú ọ lọ ní ọ̀nà ti tààrà.

12Nígbà tí o rìn, ìgbésẹ̀ rẹ kò ní ní ìdíwọ́

nígbà tí o bá sáré, ìwọ kì yóò kọsẹ̀.

13Di ẹ̀kọ́ mú, má ṣe jẹ́ kí ó lọ;

tọ́jú u rẹ̀ dáradára nítorí òun ni ìyè rẹ.

14Má ṣe gbé ẹsẹ̀ rẹ sí ojú ọnà àwọn ènìyàn búburú

tàbí kí o rìn ní ọ̀nà àwọn ẹni ibi.

15Yẹra fún un, má ṣe rìn níbẹ̀;

yàgò fún un kí o sì bá ọ̀nà tìrẹ lọ

16Nítorí wọn kò le sùn àyàfi tí wọ́n bá ṣe ibi,

wọn kò ní tòògbé àyàfi tí wọ́n bá gbé ẹlòmíràn ṣubú

17Wọ́n ń jẹ oúnjẹ ìwà búburú

wọ́n sì ń mu wáìnì ìwà ìkà.

18Ipa ọ̀nà olódodo dàbí àṣẹ̀ṣẹ̀yọ oòrùn

tí ń tànmọ́lẹ̀ sí i títí ọjọ́ fi kanrí

19ṣùgbọ́n ọ̀nà ènìyàn búburú dàbí òkùnkùn biribiri;

wọn kò mọ ohun tí ó ń mú wọn kọsẹ̀.

20Ọmọ mi, tẹ́tí sí ohun tí mo sọ;

fetísílẹ̀ dáradára sí ọ̀rọ̀ mi

21Má ṣe jẹ́ kí wọ́n rá mọ́ ọ lójú

pa wọ́n mọ́ sínú ọkàn rẹ;

22Nítorí ìyè ni wọ́n jẹ́ fún gbogbo ẹni tí ó rí wọn

àti ìlera fún gbogbo ara ènìyàn

23Ju gbogbo nǹkan tókù lọ, pa ọkàn rẹ mọ́

Nítorí òun ni orísun ìyè,

24Mú àrékérekè kúrò ní ẹnu rẹ;

sì jẹ́ kí ọ̀rọ̀ ìsọkúsọ jìnnà réré sí ẹnu rẹ.

25Jẹ́ kí ojú rẹ máa wo iwájú,

jẹ́ kí ìwo ojú rẹ máa wo ọ̀kánkán iwájú rẹ sá á.

264.26: (Gk): Hb 12.13.Kíyèsi ìrìn ẹsẹ̀ rẹ

sì rìn ní àwọn ọ̀nà tí ó dára nìkan

27Má ṣe yà sọ́tùn ún tàbí sósì;

pa ẹsẹ̀ rẹ mọ́ kúrò nínú ibi.