Nehemiah 10 – YCB & PCB

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Nehemiah 10:1-39

1Àwọn tí ó fi èdìdì dì í ni:

Nehemiah baálẹ̀, ọmọ Hakaliah.

Sedekiah 2Seraiah, Asariah, Jeremiah,

3Paṣuri, Amariah, Malkiah,

4Hattusi, Ṣebaniah, Malluki,

5Harimu, Meremoti, Ọbadiah,

6Daniẹli, Ginetoni, Baruku,

7Meṣullamu, Abijah, Mijamini,

8Maasiah, Bilgai àti Ṣemaiah.

Àwọn wọ̀nyí ni àwọn àlùfáà.

9Àwọn ọmọ Lefi:

Jeṣua ọmọ Asaniah, Binnui ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Henadadi, Kadmieli,

10àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ wọn: Ṣebaniah,

Hodiah, Kelita, Pelaiah, Hanani,

11Mika, Rehobu, Haṣabiah,

12Sakkuri, Ṣerebiah, Ṣebaniah,

13Hodiah, Bani àti Beninu.

14Àwọn olórí àwọn ènìyàn:

Paroṣi, Pahati-Moabu, Elamu, Sattu, Bani,

15Bunni, Asgadi, Bebai.

16Adonijah, Bigfai, Adini,

17Ateri, Hesekiah, Assuri,

18Hodiah, Haṣumu, Besai,

19Harifu, Anatoti, Nebai,

20Magpiaṣi, Meṣullamu, Hesiri

21Meṣesabeli, Sadoku, Jaddua

22Pelatiah, Hanani, Anaiah,

23Hosea, Hananiah, Haṣubu,

24Halloheṣi, Pileha, Ṣobeki,

25Rehumu, Haṣabna, Maaseiah,

26Ahijah, Hanani, Anani,

27Malluki, Harimu, àti Baanah.

28“Àwọn ènìyàn tókù—àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi, àwọn aṣọ́nà, àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti gbogbo àwọn tí wọ́n ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn àjèjì nítorí òfin Ọlọ́run, papọ̀ pẹ̀lú ìyàwó wọn, gbogbo ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wọn, tí òye yé 29gbogbo wọn fi ara mọ́ àwọn arákùnrin wọn, àwọn ọlọ́lá, wọ́n sì fi ègún àti ìbúra dé ara wọn láti máa tẹ̀lé òfin Ọlọ́run tí a fi fún wọn ní ipasẹ̀ Mose ìránṣẹ́ Ọlọ́run àti láti pa gbogbo àṣẹ, ìlànà àti òfin Olúwa, wa mọ́ dáradára.

30“A ti ṣe ìlérí pé, a kò ní fi àwọn ọmọbìnrin wa fún àwọn tí wọ́n wà ní àyíká wa bí ìyàwó, tàbí fẹ́ àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin wa.

31“Nígbà tí àwọn ènìyàn àdúgbò bá mú ọjà tàbí oúnjẹ wá ní ọjọ́ ìsinmi láti tà, àwa kò ní rà á ní ọwọ́ wọn ní ọjọ́ ìsinmi tàbí ní ọjọ́ mímọ́ kankan. Ní gbogbo ọdún keje àwa kò ní ro ilẹ̀ náà, a ó sì pa gbogbo àwọn gbèsè rẹ́.

32“Àwa gbà ojúṣe láti máa pa àṣẹ mọ́ pé a ó máa san ìdámẹ́ta ṣékélì ní ọdọọdún fún iṣẹ́ ilé Ọlọ́run wa: 33Nítorí oúnjẹ tí ó wà lórí tábìlì; nítorí ọrẹ ohun jíjẹ àti ẹbọ sísun ìgbà gbogbo; nítorí ọrẹ ọjọ́ ìsinmi, ti àyajọ́ oṣù tuntun àti àjọ̀dún tí a yàn; nítorí ọrẹ mímọ́; nítorí ọrẹ ẹ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù fún Israẹli; àti fún gbogbo iṣẹ́ ilé Ọlọ́run wa.

34“Àwa, àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi àti àwọn ènìyàn náà ti dìbò láti pinnu ìgbà tí olúkúlùkù àwọn ìdílé yóò mú ọrẹ igi wá láti sun lọ́ríi pẹpẹ Olúwa Ọlọ́run wa sí ilé Ọlọ́run wa, ní àkókò tí a yàn ní ọdọọdún. Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sínú ìwé òfin.

35“Àwa tún gbà ojúṣe láti mú àkọ́so àwọn èso wa wá àti gbogbo èso igi wá ní ilé Olúwa.

36“Gẹ́gẹ́ bí a sì ti kọ ọ́ sínú ìwé òfin, àwa yóò mú àkọ́bí àwọn ọmọkùnrin wa, ti ohun ọ̀sìn wa, ti àwọn abo màlúù àti ti àwọn àgùntàn wa, wá sí ilé Ọlọ́run wa, fún àwọn àlùfáà tí ń ṣiṣẹ́ níbẹ̀.

37“Síwájú sí i, àwa yóò mú àkọ́so oúnjẹ ilẹ̀ wa ti ọrẹ oúnjẹ, ti gbogbo èso àwọn igi àti ti wáìnì tuntun wa àti ti òróró wá sí yàrá ìkó-nǹkan-pamọ́-sí ilé Ọlọ́run wa àti fún àwọn àlùfáà. Àwa yóò sì mú ìdámẹ́wàá ohun ọ̀gbìn wá fún àwọn ọmọ Lefi, nítorí àwọn ọmọ Lefi ni ó ń gba ìdámẹ́wàá ní gbogbo àwọn ìlú tí a ti ń ṣiṣẹ́. 38Àlùfáà tí o ti ìdílé Aaroni wá ni yóò wá pẹ̀lú àwọn ọmọ Lefi nígbà tí wọ́n bá ń gba ìdámẹ́wàá, àwọn ọmọ Lefi yóò sì mú ìdámẹ́wàá ti ìdámẹ́wàá náà wá sí ilé Ọlọ́run, sí yàrá ìkó-nǹkan-pamọ́-sí inú ilé ìṣúra. 39Àwọn ènìyàn Israẹli, àti àwọn ọmọ Lefi gbọdọ̀ mú ọrẹ oúnjẹ, wáìnì tuntun àti òróró wá sí yàrá ìkó-nǹkan-pamọ́-sí níbi tí a pa ohun èlò ibi mímọ́ mọ́ sí àti ibi tí àwọn àlùfáà tí ń ṣe ìránṣẹ́ lọ́wọ́, àwọn aṣọ́nà àti àwọn akọrin máa ń dúró sí.

“Àwa kì yóò gbàgbé tàbí ṣe àìbìkítà nípa ilé Ọlọ́run wa.”

Persian Contemporary Bible

نحميا 10:1-39

1نحميای حاكم، اولين كسی بود كه اين پيمان را امضا كرد. بعد از او صدقيا، سپس افراد زير آن را امضا كردند:

2‏-8كاهنان:

سرايا، عزريا، ارميا،

فشحور، امريا، ملكيا،

حطوش، شبنيا، ملوک،

حاريم، مريموت، عوبديا،

دانيال، جنتون، باروک،

مشلام، ابيا، ميامين،

معزيا، بلجای، شمعيا.

9‏-13لاويان:

يشوع (پسر ازنيا)، بنوی (پسر حيناداد)،

قدمی‌ئيل، شبنيا، هوديا، قليطا،

فلايا، حانان، ميخا، رحوب،

حشبيا، زكور، شربيا، شبنيا،

هوديا، بانی، بنينو.

14‏-27سران قوم:

فرعوش، فحت موآب، عيلام، زتو،

بانی، بونی، عزجد، ببای،

ادونيا، بغوای، عودين، عاطير،

حزقيا، عزور، هوديا، حاشوم،

بيصای، حاريف، عناتوت،

نيبای، مجفيعاش، مشلام،

حزير، مشيزبئيل، صادوق،

يدوع، فلطيا، حانان، عنايا،

هوشع، حننيا، حشوب، هلوحيش،

فلحا، شوبيق، رحوم، حشبنا،

معسيا، اخيا، حانان، عانان،

ملوک، حاريم، بعنه.

متن پيمان

28ما مردم اسرائيل، كاهنان، لاويان، نگهبانان، دسته سرايندگان، خدمتگزاران خانهٔ خدا، و تمام كسانی كه با زنان، پسران و دختران بالغ خويش كه با اطاعت از تورات خدا، خود را از قومهای بيگانه جدا كرده‌ايم، 29به اين وسيله با برادران و سران قوم خود متحد شده، قسم می‌خوريم كه دستورات خدا را كه توسط خدمتگزارش موسی داده شد اطاعت كنيم؛ و اگر از احكام و اوامر او سرپيچی كنيم لعنت خدا بر ما باشد.

30قول می‌دهيم كه نه دختران خود را به پسران غيريهودی بدهيم و نه بگذاريم پسران ما با دختران غيريهودی ازدواج كنند.

31همچنين قول می‌دهيم كه اگر قومهای بيگانه در روز سَبَت يا در يكی از روزهای مقدس ديگر بخواهند به ما غله يا چيز ديگری بفروشند، از ايشان نخريم و هر هفت سال يک بار چيزی در زمين نكاريم و قرض برادران يهودی خود را ببخشيم.

32عهد می‌بنديم كه هر سال هر يک از ما يک سوم مثقال نقره برای مخارج خانهٔ خدا تقديم كنيم، 33يعنی برای نان مقدس، هديهٔ آردی و قربانیهای سوختنی روزانه، قربانیهای روزهای سبت و جشنهای ماه نو و جشنهای ساليانه، هدايای مقدس ديگر، قربانی گناه برای كفاره قوم اسرائيل، و برای تمام خدمات خانهٔ خدای ما.

34ما كاهنان، لاويان و مردم قول می‌دهيم كه مطابق دستور تورات، هيزم مورد نياز قربانگاه خانهٔ خداوند، خدايمان را تهيه كنيم و هر سال قرعه خواهيم انداخت تا معلوم شود چه قبيله‌ای بايد اين كار را انجام دهد.

35قول می‌دهيم نوبر غله و ميوهٔ خود را هر سال به خانهٔ خداوند بياوريم.

36قول می‌دهيم كه پسران ارشد و تمام نخست‌زاده‌های گله و رمه خود را مطابق دستور تورات به خانهٔ خدای خود بياوريم و به دست كاهنانی كه در آنجا خدمت می‌كنند بسپاريم.

37همچنين قول می‌دهيم خميری را كه از نوبر غله تهيه می‌كنيم همراه نوبر انواع ميوه‌ها و نوبر شراب تازه و روغن زيتون خود به كاهنانی كه در خانهٔ خدا هستند بدهيم. ما ده يک تمام محصولات زمين خود را به لاويانی كه در روستاهای ما مسئول جمع‌آوری ده يک هستند خواهيم داد. 38در وقت جمع‌آوری ده يک، كاهنی (كه از نسل هارون است) همراه لاويان خواهد بود و لاويان يک دهم از ده‌يکها را به خانه خدای ما خواهند آورد و آنجا انبار خواهند كرد. 39ما مردم اسرائيل و لاويان، اين هدايای غله، شراب تازه و روغن زيتون را به خانه خدا خواهيم آورد و در اتاقهايی كه وسايل خانهٔ خدا نگهداری می‌شود و كاهنان، نگهبانان و سرايندگان در آنجا زندگی می‌كنند، انبار خواهيم كرد.

قول می‌دهيم كه از خانهٔ خدا غافل نشويم.