2 Tẹsalonika 2 – YCB & NTLR

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

2 Tẹsalonika 2:1-17

Ọkùnrin aláìlófin náà

12.1: 1Tẹ 4.15-17.Ní ti bíbọ̀ Jesu Kristi Olúwa wa, àti ti ìpéjọ wa sọ́dọ̀ rẹ̀, àwa wí fún yín ará, 22.2: 2Tẹ 3.17.kí ọkàn yín má ṣe àìbalẹ̀, tàbí kí ẹ má ṣe jáyà nípa àsọtẹ́lẹ̀, ìròyìn tàbí lẹ́tà tí ó lè fi ara jọ èyí tí ó le wá láti ọ̀dọ̀ wa, tí yóò máa wí pé ọjọ́ Olúwa ti dé ná. 32.3: Ef 5.6-8; Da 7.8,25; 11.36; If 13.5; Jh 17.12.Ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni kí ó tàn yín jẹ ní ọ̀nàkọnà, nítorí pé ọjọ́ náà kì yóò dé, bí kò ṣe pé ìṣọ̀tẹ̀ bá kọ́ ṣẹlẹ̀, tí a sì fi ẹni ẹ̀ṣẹ̀ hàn, tí í ṣe ọmọ ègbé. 42.4: El 28.2.Òun yóò lòdì sí, yóò sì gbé ara rẹ̀ ga sí gbogbo ohun tí a ń pè ní Ọlọ́run tàbí tí a ń sìn, dé ibi pé yóò gbé ara rẹ̀ jókòó nínú tẹmpili Ọlọ́run, tí yóò sì pe ara rẹ̀ ní Ọlọ́run.

52.5: 1Tẹ 3.4.Ṣé ẹ̀yin kò rántí pé nígbà tí mo wà pẹ̀lú yín, mo ń sọ àwọn nǹkan wọ̀nyí fún un yín. 6Àti pé nísinsin yìí, ẹ̀yin mọ ohun tí ń dá a dúró, kí a bá a lè fi í hàn ní àkókò rẹ̀ gan an. 7Nítorí agbára ìkọ̀kọ̀ ẹni ẹ̀ṣẹ̀ ti ń ṣiṣẹ́; ṣùgbọ́n ẹni tí ń dènà yóò máa ṣe bẹ́ẹ̀ títí a ó fi mú un kúrò ní ọ̀nà. 82.8: Isa 11.4.Nígbà náà ni a ó fi ẹni ẹ̀ṣẹ̀ hàn, ẹni tí Jesu Olúwa yóò fi èémí ẹnu rẹ̀ pa, tí yóò sì fi ọlá ìpadàbọ̀ rẹ̀ parun. 92.9: Mt 24.24; Jh 4.48.Wíwá ẹni ẹ̀ṣẹ̀ yóò rí bí iṣẹ́ Satani, gbogbo èyí tí a fihàn gẹ́gẹ́ bí àdàmọ̀dì iṣẹ́ ìyanu, àdàmọ̀dì ààmì àti àdàmọ̀dì idán, 10Ní gbogbo ọ̀nà búburú tí a fi ń tan àwọn tí ń ṣègbé jẹ. Wọ́n ṣègbé nítorí wọ́n kọ̀ láti fẹ́ràn òtítọ́ kí wọn sì di ẹni ìgbàlà. 112.11: Ro 1.28.Nítorí ìdí èyí, Ọlọ́run rán ohun tó ń ṣiṣẹ́ ìṣìnà sí wọn kí wọn lè gba èké gbọ́, 12kí wọn kí ó lè gba ìdálẹ́bi, àní àwọn tí kò gba òtítọ́ gbọ́, ṣùgbọ́n tí wọ́n ní inú dídùn nínú ìwà búburú.

Ẹ dúró ṣinṣin

132.13: 2Tẹ 1.3; Ef 1.4; 1Pt 1.2.Ṣùgbọ́n, ohun tí ó tọ́ fún wa ni láti máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run nígbà gbogbo nítorí yín, ará olùfẹ́ ní ti Olúwa, nítorí láti ìbẹ̀rẹ̀ ni Ọlọ́run ti yàn yín sí ìgbàlà nípa ìsọdimímọ́ ti Ẹ̀mí àti nípa gbígba òtítọ́ gbọ́. 14Òun ti pè yín sí èyí nípa ìhìnrere wa, kí ẹ̀yin kí ó lè pín nínú ògo Jesu Kristi Olúwa wa.

152.15: 1Kọ 16.13; 11.2.Nítorí náà ará, ẹ dúró ṣinṣin, kí ẹ sì di àwọn ẹ̀kọ́ wọ̀n-ọn-nì tí a kọ́ yín mú, yálà nípa ọ̀rọ̀ ẹnu tàbí lẹ́tà.

162.16: 1Tẹ 3.11; 1Pt 1.3.Ǹjẹ́ kí Jesu Kristi Olúwa wa tìkálára rẹ̀, àti Ọlọ́run baba wa, ẹni to ti fẹ́ wa, tí ó sì ti fi ìtùnú àìnípẹ̀kun àti ìrètí rere nípa oore-ọ̀fẹ́ fún wa. 17Kí ó mú ọkàn yín le, kí ó sì kún yín pẹ̀lú agbára nínú iṣẹ́ gbogbo àti ọ̀rọ̀ rere gbogbo.

Nouă Traducere În Limba Română

2 Tesaloniceni 2:1-17

Omul fărădelegii

1În ce privește venirea Domnului nostru Isus Cristos și strângerea noastră laolaltă cu El, vă rugăm, fraților, 2să nu vă lăsați clătinați sau tulburați așa de repede în mintea voastră nici de vreun duh, nici de vreun cuvânt, nici de vreo scrisoare ca venind din partea noastră, care spune că ziua Domnului a și venit. 3Nimeni să nu vă înșele în niciun fel, fiindcă nu va veni înainte să vină apostazia3 Sau: răzvrătirea. și să fie descoperit omul fărădelegii3 Unele mss conțin: omul păcatului., fiul pierzării, 4cel care se împotrivește și se înalță pe sine deasupra a orice este numit „dumnezeu“ sau obiect de închinare. El se va așeza în Templul lui Dumnezeu, declarându‑se pe sine însuși Dumnezeu4 Sau: un zeu; sau: divin..

5Nu vă aduceți aminte că v‑am spus aceste lucruri când eram cu voi? 6Și acum știți ceea ce‑l oprește, astfel încât să fie descoperit doar la vremea lui. 7Căci taina fărădelegii lucrează deja. Trebuie doar ca acela care‑l oprește acum să se dea la o parte. 8Și atunci va fi descoperit cel fără de Lege, pe care Domnul Isus îl va omorî cu suflarea gurii Sale și‑l va distruge la manifestarea venirii Sale. 9Venirea celui fără de Lege va fi potrivit cu lucrarea lui Satan9 Cuvânt împrumutat din ebraică, însemnând vrăjmaș sau acuzator. Ulterior acesta a devenit un nume propriu folosit cu referire la cel care este acuzatorul, în mod special în perioada NT. Termenul diabolos este traducerea grecească a lui Satan., cu tot felul de lucrări puternice, semne și minuni mincinoase 10și cu tot felul de înșelăciuni ale nedreptății pentru cei ce pier, având în vedere că n‑au primit dragostea adevărului ca să fie mântuiți. 11De aceea, Dumnezeu le trimite o lucrare de rătăcire, pentru ca ei să creadă minciuna, 12așa încât toți cei care n‑au crezut adevărul, ci și‑au găsit plăcerea în nedreptate, să fie condamnați.

Rămâneți tari!

13Însă noi Îi mulțumim întotdeauna lui Dumnezeu pentru voi, frați iubiți de Domnul, pentru că Dumnezeu v‑a ales ca prim rod pentru mântuire13 Mss bizantine redau: pentru că Dumnezeu v‑a ales de la început pentru mântuire., prin lucrarea de sfințire a Duhului și prin credința în adevăr. 14Și la aceasta v‑a chemat El prin Evanghelia noastră, astfel încât să intrați în posesia slavei Domnului nostru Isus Cristos.

15Așadar, fraților, rămâneți tari și țineți tradițiile15 În acest context apostolul se referă la tradiții cu o conotație pozitivă, acele credințe și practici care păstrează sănătatea spirituală și stabilitatea bisericii locale. în care ați fost învățați, fie prin cuvânt, fie prin scrisoarea noastră.

16Însuși Domnul nostru Isus Cristos și Dumnezeu, Tatăl nostru, Care ne‑a iubit și Care ne‑a dat, prin harul Său, o încurajare veșnică și o speranță bună, 17să vă încurajeze inimile și să vă întărească în orice faptă și cuvânt bun!