Àwọn olùkọ́ni èké àti ìparun wọn
12.1-18: Jd 4-16.Ṣùgbọ́n àwọn wòlíì èké wà láàrín àwọn ènìyàn náà pẹ̀lú, gẹ́gẹ́ bí àwọn olùkọ́ni èké yóò ti wà láàrín yín. Wọn yóò yọ́ kẹ́lẹ́ mú ẹ̀kọ́ òdì àti ègbé tọ̀ yín wa, àní tí yóò sẹ́ Olúwa tí ó rà wọ́n padà, wọ́n ó sì mú ìparun ti o yára kánkán wá sórí ara wọn. 2Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni yóò si máa tẹ̀lé ọ̀nà ìtìjú wọn, tí wọn yóò sì mú kí ọ̀nà òtítọ́ di ìsọ̀rọ̀-òdì sí. 3Nínú ìwà wọ̀bìà wọn, àwọn ẹlẹ́kọ̀ọ́ òdì wọ̀nyí yóò máa rẹ́ ẹ yín jẹ nípa ìtàn asán. Ìdájọ́ ẹni tí kò falẹ̀ láti ìgbà yìí wá àti ìparun wọn tí kò sí tòògbé.
4Nítorí pé bi Ọlọ́run kò bá dá àwọn angẹli si nígbà tí wọn ṣẹ̀, ṣùgbọ́n ti ó sọ wọ́n sí ìsàlẹ̀ ọ̀run àpáàdì tí ó sì fi wọ́n sínú ọ̀gbun òkùnkùn biribiri nínú ìfipamọ́ títí dé ìdájọ́. 52.5: Gẹ 8.18; 6.6-8.Bí òun kò si dá ayé ìgbàanì sí, nígbà tí ó mú ìkún omi wá sórí ayé àwọn aláìwà-bí-Ọlọ́run, ṣùgbọ́n ó pa Noa mọ́, oníwàásù òdodo, pẹ̀lú àwọn ọmọ méje mìíràn. 62.6: Gẹ 19.24.Tí ó sọ àwọn ìlú Sodomu àti Gomorra di eérú, nígbà tí ó fi ìparun pátápátá dá wọn lẹ́bi, tí ó fi wọ́n ṣe àpẹẹrẹ fún àwọn tí yóò jẹ́ aláìwà-bí-Ọlọ́run. 72.7: Gẹ 19.16,29.Tí ó sì yọ Lọti olóòtítọ́ ènìyàn, ẹni tí ìwà ẹ̀gbin àwọn ènìyàn láìlófin bà nínú jẹ́; 8(nítorí ọkùnrin olóòtítọ́ náà bí ó ti ń gbé àárín wọn, tí ó ń rí, tí ó sì ń gbọ́, lójoojúmọ́ ni ìwà búburú wọn ń bá ọkàn òtítọ́ rẹ̀ jẹ́) 9Bí ó bá rí bẹ́ẹ̀, Olúwa mọ bí a tí ń yọ àwọn ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run kúrò nínú ìdánwò àti bí a ti ń pa àwọn aláìṣòótọ́ mo fún ọjọ́ ìdájọ́ nígbà tí wọn yóò tẹ̀síwájú nínú ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn. 10Ṣùgbọ́n pàápàá àwọn tí ó ń tọ ẹran-ara lẹ́yìn nínú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ìwà èérí, tí wọ́n sì ń gan àwọn ìjòyè.
Àwọn ọ̀dájú àti agbéraga, wọn kò bẹ̀rù láti sọ̀rọ̀ ẹ̀gàn sí àwọn ẹni ògo. 11Bẹ́ẹ̀ ni àwọn angẹli bí wọ́n ti pọ̀ ní agbára àti ipá tó o nì, wọn kò dá wọ́n lẹ́jọ́ ẹ̀gàn níwájú Olúwa. 12Ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí, bí ẹranko igbó tí kò ní èrò, ẹranko sá á tí a dá láti máa mú pa, wọ́n ń sọ̀rọ̀ ẹ̀gàn nínú ọ̀rọ̀ tí kò yé wọn, a ó pa wọn run pátápátá nínú ìbàjẹ́ ara wọn.
13Wọn yóò gba ibi padà bí ibi tí wọ́n ti ṣe. Òye ìgbafẹ́ tí wọ́n ní láti máa jẹ adùn ayé. Wọ́n jẹ́ àbàwọ́n àti àbùkù, wọ́n ń jayé nínú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ wọn nígbà tí wọ́n bá ń jẹ àsè pẹ̀lú yín. 14Ojú wọn kún fún panṣágà, wọn kò sì dẹ́kun ẹ̀ṣẹ̀ dídá; wọ́n ń tan àwọn tí ọkàn kò fi ẹsẹ̀ múlẹ̀ jẹ; àwọn tí wọ́n ní ọkàn tí ó ti yege nínú wọ̀bìà, ọmọ ègún ni wọ́n. 152.15: Nu 22.5,7.Wọ́n kọ ọ̀nà tí ó tọ́ sílẹ̀, wọ́n sì ṣáko lọ, wọ́n tẹ̀lé ọ̀nà Balaamu ọmọ Beori, ẹni tó fẹ́ràn èrè àìṣòdodo. 162.16: Nu 22.21,23,28,30-31.Ṣùgbọ́n a bá a wí nítorí ìrékọjá rẹ̀, odi kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ fi ohùn ènìyàn sọ̀rọ̀, ó sì fi òpin sí ìṣiwèrè wòlíì náà.
17Àwọn wọ̀nyí ni kànga tí kò ní omi, ìkùùkuu tí ẹ̀fúùfù ń gbá kiri; àwọn ẹni tí a pa òkùnkùn biribiri mọ́ dè títí láé. 18Nítorí ìgbà tí wọ́n bá ń sọ̀rọ̀ ìhàlẹ̀ asán, nínú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara, wọn a máa tan àwọn tí wọ́n fẹ́rẹ̀ má tí ì bọ́ tán kúrò lọ́wọ́ àwọn tí wọ́n wà nínú ìṣìnà. 19Wọn a máa ṣe ìlérí òmìnira fún wọn, nígbà tí àwọn pàápàá jẹ́ ẹrú ìdíbàjẹ́; nítorí ènìyàn tí di ẹrú ohunkóhun tí ó bá ṣe ọ̀gá rẹ̀. 20Lẹ́yìn tí wọ́n bá ti yọ tán kúrò nínú èérí ayé nípa mímọ́ Olúwa àti Olùgbàlà wá Jesu Kristi, bí wọn bá sì tún fi ara kó o, tí a sì ṣẹ́gun wọn, ìgbẹ̀yìn wọn a burú jú ti ìṣáájú lọ. 21Nítorí ìbá sàn fún wọn, kí wọn má mọ́ ọ̀nà òdodo, jù pé lẹ́yìn tí wọ́n mọ̀ ọ́n tán, kí wọn yípadà kúrò nínú òfin mímọ́ tí a fi fún wọn. 222.22: Òw 26.11.Òwe òtítọ́ náà ṣẹ sí wọn lára: “Ajá tún padà sí èébì ara rẹ̀; àti ẹlẹ́dẹ̀ tí a ti wẹ̀mọ́ tún padà ń yíràá nínú ẹrọ̀fọ̀.”
معلمين دروغين و عاقبت كار آنان
1اما در آن روزگاران، انبيای دروغين نيز بودند، همانطور كه در ميان شما نيز معلمين دروغين پيدا خواهند شد كه با نيرنگ، دروغهايی دربارهٔ خدا بيان خواهند كرد و حتی با سَرور خود، مسيح كه ايشان را با خون خود خريده است، سر به مخالفت برخواهند داشت. اما ناگهان سرنوشتی هولناک دچار آنها خواهد شد. 2عدهای بسيار، تعاليم مضر و خلاف اخلاق ايشان را پيروی خواهند كرد و به سبب همين افراد، راه مسيح مورد اهانت و تمسخر قرار خواهد گرفت.
3اين معلمنماها از روی طمع، با هرگونه سخنان نادرست خواهند كوشيد پول شما را به چنگ بياورند. اما خدا از مدتها پيش ايشان را محكوم فرموده؛ پس نابودیشان نزديک است. 4خدا حتی از سر تقصير فرشتگانی كه گناه كردند نگذشت، بلكه ايشان را در ظلمت جهنم محبوس فرمود تا زمان داوری فرا رسد. 5همچنين، در روزگاران گذشته، پيش از طوفان، بر هيچكس ترحم نفرمود، جز بر نوح كه راه راست خدا را اعلام میكرد، و بر خانوادهٔ او كه هفت نفر بودند. در آن زمان، خدا همهٔ مردم خدانشناس دنيا را با طوفانی عالمگير به کلی نابود ساخت. 6مدتها پس از آن، خدا شهرهای «سدوم» و «عموره» را به تلی از خاكستر تبديل نمود و از صفحهٔ روزگار محو ساخت، تا در آينده درسی باشد برای تمام خدانشناسان و بیدينان.
7-8اما در همان زمان، خدا «لوط» را از سدوم نجات داد، زيرا او مرد درستكاری بود و از رفتار و سخنان قبيح و هرزه و گناهآلودی كه هر روز از ساكنان شهر میديد و میشنيد، رنج میبرد و به تنگ میآمد. 9به همين ترتيب خدا میتواند من و شما را نيز از وسوسههای اطرافمان رهايی بخشد و به مجازات مردم خدانشناس ادامه دهد تا سرانجام روز داوری فرا برسد. 10مجازات خدا خصوصاً بر كسانی سخت خواهد بود كه به دنبال خواستههای ناپاک و جسمانی خود میروند و تابع هيچ قدرتی نيستند. اينان چنان گستاخ هستند كه حتی موجودات آسمانی را نيز به باد تمسخر میگيرند؛ 11در حالی که فرشتگان آسمانی كه در حضور خدا هستند و صاحب قدرت و قوتی بسيار برتر از اين معلمنماها میباشند، هرگز به اين موجودات توهين نمیكنند.
12اين معلمين دروغين و فريبكار، مانند حيوانات وحشی كه برای شكار و كشته شدن آفريده شدهاند، فقط بر اساس غريزهٔ خود عمل میكنند، و هر كاری را كه غريزهشان حكم میكند، انجام میدهند. اينان، هر چه را كه نمیفهمند مسخره میكنند، غافل از اينكه روزی مانند همان حيوانات نابود خواهند شد.
13بلی، مزد اين معلمنماها همين است، زيرا روزهای عمر خود را به خوشگذرانیهای گناهآلود میگذرانند. وجود ايشان در ميان شما باعث ننگ و رسوايی است؛ خود را درستكار نشان میدهند تا در ضيافتهای كليسايی شما داخل شوند. 14به هر زنی با نظر ناپاک نگاه میكنند و از زناكاری هرگز سير نمیشوند؛ زنان بیاراده را به نيرنگ به دام میاندازند؛ ايشان خود را طمعكار بار آوردهاند و زير لعنت و محكوميت خدا قرار دارند. 15از راه راست خارج شده، مانند «بلعام» پسر «بعور» گمراه شدهاند. بلعام پولی را كه از انجام ناراستی به دست میآورد، دوست میداشت؛ 16اما وقتی الاغ او به زبان انسان به حرف آمد و او را سرزنش و توبيخ كرد، از رفتار نادرست خود دست كشيد.
17اين اشخاص همچون چشمههای خشكيده، نفعی به كسی نمیرسانند، و مانند ابرهايی كه به هر سو رانده میشوند، ناپايدارند و تاريكی ابدی جهنم انتظارشان را میكشد. 18ايشان به گناهان و اعمال ناپاک خود میبالند، و آنان را كه تازه از چنين زندگی گناهآلودی نجات يافتهاند، با استفاده از فريب شهوت، باز به دام گناه میكشانند، 19و میگويند: «كسی كه نجات يافته، آزاد است هر كاری میخواهد بكند و هيچ كار او گناه به حساب نخواهد آمد.» در حالی که خودشان نيز آزاد نيستند بلكه اسير شهوات میباشند، زيرا انسانی كه تحت تسلط چيزی است، اسير آن میباشد.
20هرگاه كسی با شناخت خداوند و نجات دهندهمان عيسی مسيح، از ناپاكیهای اين دنيا رهايی يابد، ولی بعد از آن، بار ديگر اسير آن آلودگیها گردد، وضعش بدتر از سابق میشود. 21اگر چيزی دربارهٔ مسيح نمیدانست، برايش بهتر بود از اينكه مسيح را بشناسد و سپس به احكام مقدسی كه به او سپرده شده است، پشت پا بزند. 22آن مَثَل قديمی چه خوب میگويد كه «سگ به قی خود باز میگردد و خوک شسته شده، بار ديگر در لجن میغلتد.» اين مثل دربارهٔ اين اشخاص صدق میكند.