Two Songs of Praise
1In days to come, the people of Israel will sing,
“Lord, we will praise you.
You were angry with us.
But now your anger has turned away from us.
And you have brought us comfort.
2God, you are the one who saves us.
We will trust in you.
Then we won’t be afraid.
Lord, you are the one who gives us strength.
You are the one who keeps us safe.
Lord, you have saved us.”
3People of Israel, he will save you.
That will bring you joy like water brought up from wells.
4In days to come, the people of Israel will sing,
“Give praise to the Lord. Make his name known.
Tell the nations what he has done.
Announce how honored he is.
5Sing to the Lord. He has done glorious things.
Let it be known all over the world.
6People of Zion, give a loud shout!
Sing for joy!
The Holy One of Israel is among you.
And he is great.”
Orin ìyìn
1Ní ọjọ́ náà ni ìwọ ó wí pé:
“Èmi ó yìn ọ́, Olúwa.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ò ti bínú sí mi
ìbínú rẹ ti yí kúrò níbẹ̀
ìwọ sì ti tù mí nínú.
2Nítòótọ́ Ọlọ́run ni ìgbàlà mi,
èmi yóò gbẹ́kẹ̀lé e èmi kì yóò bẹ̀rù.
Olúwa, Olúwa náà ni agbára à mi àti orin ìn mi,
òun ti di ìgbàlà mi.”
3Pẹ̀lú ayọ̀ ni ìwọ yóò máa pọn omi
láti inú kànga ìgbàlà.
4Ní ọjọ́ náà, ìwọ yóò wí pé:
“Fi ọpẹ́ fún Olúwa, ké pe orúkọ rẹ̀,
Jẹ́ kí ó di mí mọ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
ohun tí ó ti ṣe
kí o sì kéde pé a ti gbé
orúkọ rẹ̀ ga.
5Kọ orin sí Olúwa, nítorí ó ti ṣe ohun tí ó lógo,
jẹ́ kí èyí di mí mọ̀ fún gbogbo ayé.
6Kígbe sókè kí o sì kọrin fún ayọ̀, ẹ̀yin ènìyàn Sioni,
nítorí títóbi ni ẹni mímọ́ kan ṣoṣo
ti Israẹli láàrín yín.”