ኢሳይያስ 53 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

ኢሳይያስ 53:1-12

1የሰማነውን ነገር ማን አመነ?

የእግዚአብሔርስ ክንድ ለማን ተገለጠ?

2በፊቱ እንደ ቡቃያ፣

ከደረቅም መሬት እንደ ወጣ ሥር በቀለ፤

የሚስብ ውበት ወይም ግርማ የለውም፤

እንድንወድደውም የሚያደርግ መልክ አልነበረውም።

3በሰዎች የተናቀና የተጠላ፣

የሕማም ሰውና ሥቃይ ያልተለየው ነበር።

ሰዎች ፊታቸውን እንደሚያዞሩበት ዐይነት፣

የተናቀ ነበር፤ እኛም አላከበርነውም።

4በርግጥ እርሱ ደዌያችንን ወሰደ፤

ሕመማችንንም ተሸከመ፤

እኛ ግን በእግዚአብሔር እንደ ተመታ፣

እንደ ተቀሠፈ፣ እንደ ተሠቃየም ቈጠርነው።

5ነገር ግን እርሱ ስለ መተላለፋችን ተወጋ፤

ስለ በደላችንም ደቀቀ፤

በእርሱ ላይ የወደቀው ቅጣት ለእኛ ሰላም አመጣልን፤

በእርሱም ቍስል እኛ ተፈወስን።

6እኛ ሁላችን እንደ በጎች ተቅበዝብዘን ጠፋን፤

እያንዳንዳችንም በየመንገዳችን ነጐድን፤

እግዚአብሔርም፣ የሁላችንን በደል

በእርሱ ላይ ጫነው።

7ተጨነቀ፤ ተሠቃየም፤

ነገር ግን አፉን አልከፈተም፤

እንደ ጠቦትም ለዕርድ ተነዳ፤

በሸላቾች ፊት ዝም እንደሚል በግ፣

አፉን አልከፈተም።

8በማስጨነቅና53፥8 ወይም፣ በእስር በፍርድ ተወሰደ፤

ስለ ሕዝቤ ኀጢአት ተመትቶ፣

ከሕያዋን ምድር እንደ ተወገደ፣

ከትውልዱ ማን አስተዋለ?

9በአፉ ተንኰል ሳይገኝበት፣

ምንም ወንጀል ሳይሠራ፣

አሟሟቱ ከክፉዎች፣

መቃብሩም ከባለጠጎች ጋር ሆነ።

10መድቀቁና መሠቃየቱ ግን የእግዚአብሔር ፈቃድ ነበር፤

እግዚአብሔር ነፍሱን የኀጢአት መሥዋዕት ቢያደርገውም እንኳ፣

ዘሩን ያያል፤ ዕድሜውም ይረዝማል፤

የእግዚአብሔርም ፈቃድ በእጁ ይከናወናል።

11ከነፍሱ ሥቃይ በኋላ፣

የሕይወት ብርሃን53፥11 የሙት ባሕር ጥቅሎች (እንዲሁም የሰብዓ ሊቃናት ትርጕምን ይመ) ከዚህ ጋር ይስማማሉ፤ የማሶሬቱ ቅጅ ግን፣ የሕይወት ብርሃን የሚለውን ሐረግ አይጨምርም። ያያል፤ ደስም ይለዋል፤

ጻድቅ ባሪያዬ በዕውቀቱ ብዙዎቹን ያጸድቃል፤

መተላለፋቸውንም ይሸከማል።

12ስለዚህ ድርሻውን ከታላላቆች53፥12 ወይም፣ ከብዙዎች ጋር ጋር እሰጠዋለሁ፤

ምርኮውን ከኀያላን53፥12 ወይም፣ እጅግ ብዙ ከሆኑ ጋር ጋር ይካፈላል፤

እስከ ሞት ድረስ ሕይወቱን አሳልፎ በመስጠቱ፣

ከክፉ አድራጊዎችም ጋር በመቈጠሩ፣

የብዙዎችን ኀጢአት ተሸከመ፤

ስለ ዐመፀኞችም ማለደ።

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Isaiah 53:1-12

153.1: Jh 12.38; Ro 10.16.Ta ni ó ti gba ìròyìn in wa gbọ́

àti ta ni a ti fi apá Olúwa hàn fún?

2Òun dàgbàsókè níwájú rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí àṣẹ̀ṣẹ̀yọ irúgbìn,

àti gẹ́gẹ́ bí i gbòǹgbò tí ó jáde láti inú ìyàngbẹ ilẹ̀.

Òun kò ní ẹwà tàbí ògo láti fà wá sọ́dọ̀ ara rẹ̀,

kò sí ohun kankan nínú àbùdá rẹ̀

tí ó fi yẹ kí a ṣàfẹ́rí i rẹ̀.

3A kẹ́gàn rẹ̀ àwọn ènìyàn sì kọ̀ ọ́ sílẹ̀,

ẹni ìbànújẹ́, tí ó sì mọ bí ìpọ́njú ti rí.

Gẹ́gẹ́ bí ẹnìkan tí àwọn ènìyàn ń fojú pamọ́ fún

a kẹ́gàn rẹ, a kò sì bu ọlá fún un rárá.

453.4: Mt 8.17.Lóòtítọ́ ó ti ru àìlera wa lọ

ó sì ti ru ìbànújẹ́ wa pẹ̀lú,

síbẹ̀ a kà á sí ẹni tí Ọlọ́run lù,

tí ó lù, tí a sì pọ́n lójú.

553.5-6: 1Pt 2.24-25.Ṣùgbọ́n a sá a lọ́gbẹ́ nítorí àìṣedéédéé wa

a pa á lára nítorí àìṣòdodo wa;

ìjìyà tí ó mú àlàáfíà wá fún wa wà lórí i rẹ̀,

àti nípa ọgbẹ́ rẹ̀ ni a fi mú wa láradá.

6Gbogbo wa bí àgùntàn, ti ṣìnà lọ,

ẹnìkọ̀ọ̀kan wa ti yà sí ọ̀nà ara rẹ̀;

Olúwa sì ti gbé e ka orí ara rẹ̀

gbogbo àìṣedéédéé wa.

753.7-8: Ap 8.32-33.A jẹ ẹ́ ní yà, a sì pọ́n ọn lójú,

síbẹ̀ kò ya ẹnu rẹ̀;

a mú un wá gẹ́gẹ́ bí ọ̀dọ́-àgùntàn sọ́dọ̀ alápatà,

àti gẹ́gẹ́ bí àgùntàn tí ó dákẹ́ níwájú olùrẹ́run rẹ̀,

síbẹ̀ kò ya ẹnu rẹ̀.

8Pẹ̀lú ìpọ́nlójú àti ìdánilẹ́jọ́ ni a mú un jáde lọ,

ta ni ó sì le sọ nípa ìrànlọ́wọ́ rẹ̀?

Nítorí a ké e kúrò ní ilẹ̀ àwọn alààyè;

nítorí àìṣedéédéé àwọn ènìyàn mi ni a ṣe lù ú.

953.9: 1Pt 2.22.A fún un ní ibojì pẹ̀lú àwọn ìkà,

àti pẹ̀lú àwọn ọlọ́rọ̀ ní ikú rẹ̀,

bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò hùwà jàgídíjàgan kan,

tàbí kí a rí ẹ̀tàn kan ní ẹnu rẹ̀.

10Síbẹ̀, ó wu Olúwa láti pa á lára

àti láti mú kí ó jìyà,

bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Olúwa fi ayé rẹ̀

fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀,

Òun yóò rí àrọ́mọdọ́mọ rẹ̀ àti ọjọ́ ayé

rẹ̀ yóò pẹ́ títí,

àti ète Olúwa ni yóò gbèrú ní ọwọ́ rẹ̀.

11Lẹ́yìn ìpọ́njú ẹ̀mí rẹ̀,

òun yóò rí ìmọ́lẹ̀, ààyè yóò sì tẹ́ ẹ lọ́rùn;

nípa ìmọ̀ rẹ̀ ìránṣẹ́ mi olódodo yóò dá ọ̀pọ̀lọpọ̀ láre,

Òun ni yóò sì ru àìṣedéédéé wọn.

1253.12: Lk 22.37.Nítorí náà èmi yóò fún un ní ìpín pẹ̀lú àwọn ẹni ńlá

òun yóò sì pín ìkógun pẹ̀lú àwọn alágbára,

nítorí pé òun jọ̀wọ́ ẹ̀mí rẹ̀ fún ikú,

tí a sì kà á mọ́ àwọn alárékọjá.

Nítorí ó ru ẹ̀ṣẹ̀ ọ̀pọ̀lọpọ̀,

ó sì ṣe ìlàjà fún àwọn alárékọjá.