ኢሳይያስ 52 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

ኢሳይያስ 52:1-15

1ጽዮን ሆይ፤ ተነሺ፤ ተነሺ፤

ኀይልን ልበሺ፤

ቅድስቲቱ ከተማ፤ ኢየሩሳሌም ሆይ!

የክብር ልብስሽን ልበሺ፤

ያልተገረዘ የረከሰም

ከእንግዲህ ወደ አንቺ አይገባም።

2ትቢያሽን አራግፊ፤

ኢየሩሳሌም ሆይ፤ ተነሺ በዙፋንሽ ላይ ተቀመጪ፤

ምርኮኛዪቱ የጽዮን ልጅ ሆይ፤

የዐንገትሽን የእስራት ሰንሰለት አውልቀሽ ጣዪ።

3እግዚአብሔር እንዲህ ይላል፤

“ያለ ዋጋ ተሸጣችሁ ነበር፤

ያለ ገንዘብ ትቤዣላችሁ።”

4ጌታ እግዚአብሔር እንዲህ ይላል፤

“በመጀመሪያ ሕዝቤ ይኖር ዘንድ ወደ ግብፅ ወረደ፤

በኋላም አሦር ያለ ምክንያት አስጨንቆ ገዛው።

5“አሁን እዚህ ምን አለኝ?” ይላል እግዚአብሔር

“ሕዝቤ ያለ ምክንያት ተወስዷል፤

የገዟቸው ተሣልቀውባቸዋል”52፥5 የሙት ባሕር ጥቅሎችና ቩልጌት ከዚህ ጋር ይስማማሉ፤ የማሶሬቱ ቅጅ ግን፣ ሙሾ ይላል።

ይላል እግዚአብሔር

“ቀኑን ሙሉ፣

ስሜ ያለ ማቋረጥ ይሰደባል።

6ስለዚህ ሕዝቤ ስሜን ያውቃል፤

በዚያ ቀንም፣

አስቀድሜ የተናገርሁ እኔ መሆኔን ይረዳል፤

እነሆ፤ እኔው ነኝ።”

7በተራሮች ላይ የቆሙ፣

የምሥራች ይዘው የሚመጡ እግሮች፣

ሰላምን የሚናገሩ፣

መልካም ዜና የሚያበሥሩ፣

ድነትን የሚያውጁ፣

ጽዮንንም፣

“አምላክሽ ነግሧል” የሚሉ እንዴት ያማሩ ናቸው።

8ስሚ፤ ጠባቂዎችሽ ድምፃቸውን ከፍ አድርገዋል፤

በአንድነት በእልልታ ይዘምራሉ።

እግዚአብሔር ወደ ጽዮን ሲመለስ፣

በዐይኖቻቸው ያያሉ።

9እናንት የኢየሩሳሌም ፍርስራሾች፣

በአንድነት በእልልታ ዘምሩ፤

እግዚአብሔር ሕዝቡን አጽናንቷል፤

ኢየሩሳሌምንም ተቤዥቷልና።

10እግዚአብሔር በመንግሥታት ሁሉ ፊት፣

የተቀደሰ ክንዱን ይገልጣል፤

በምድር ዳርቻዎች ያሉ ሁሉ፣

የአምላካችንን ማዳን ያያሉ።

11እናንት የእግዚአብሔርን ዕቃ የምትሸከሙ፣

ተለዩ፤ ተለዩ፤ ከዚያ ውጡ፤

ርኩስ ነገር አትንኩ፤

ከዚያ ውጡ ንጹሓንም ሁኑ።

12ሆኖም በችኰላ አትወጡም፤

ሸሽታችሁም አትሄዱም፤

እግዚአብሔር ፊት ፊታችሁ ይሄዳል፤

የእስራኤል አምላክ ደጀን ይሆናችኋል።

የባሪያው ሥቃይና ክብር

13እነሆ፤ ባሪያዬ የሚያከናውነው በማስተዋል ነው፤52፥13 ወይም ባሪያዬ ይበለጽጋል

ገናና ይሆናል፤ ከፍ ከፍ ይላል፤ እጅግ ይከብራልም።

14ብዙዎች በእርሱ52፥14 ዕብራይስጡ፣ በአንተ ይላል። እስኪደነግጡ ድረስ፣

መልኩ ከማንም ሰው ተለየ፤

ከሰው ልጆችም ሁሉ ይልቅ ተጐሳቈለ።

15ስለዚህ ብዙ መንግሥታትን ያስደንቃል፤

በእርሱ ምክንያት ነገሥታት አፋቸውን ይይዛሉ፤

ያልተነገራቸውን ያያሉ፤

ያልሰሙትን ያስተውላሉ።

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Isaiah 52:1-15

152.1: If 21.27.Jí, jí, Ìwọ Sioni,

wọ ara rẹ ní agbára.

Gbé aṣọ ògo rẹ wọ̀,

ìwọ Jerusalẹmu, ìlú mímọ́ n nì.

Àwọn aláìkọlà àti aláìmọ́

kì yóò wọ inú rẹ mọ́.

2Gbọn eruku rẹ kúrò;

dìde sókè, kí o sì gúnwà, Ìwọ Jerusalẹmu.

Bọ́ ẹ̀wọ̀n tí ń bẹ lọ́rùn rẹ kúrò,

ìwọ ọ̀dọ́mọbìnrin ìgbèkùn Sioni.

3Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa wí;

“Ọ̀fẹ́ ni a tà ọ́,

láìsanwó ni a ó sì rà ọ́ padà.”

4Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí.

“Ní ìgbà àkọ́kọ́ àwọn ènìyàn mi sọ̀kalẹ̀

lọ sí Ejibiti láti gbé;

láìpẹ́ ni Asiria pọ́n wọn lójú.

552.5: Ro 2.24.“Àti ní àkókò yìí, kí ni mo ní níbí?” ni Olúwa wí.

“Nítorí a ti kó àwọn ènìyàn mi lọ lọ́fẹ̀ẹ́,

àwọn tí ó sì ń jẹ ọba lórí wọn fi wọ́n ṣẹlẹ́yà,”

ni Olúwa wí.

“Àti ní ọjọọjọ́

orúkọ mi ni asọ̀rọ̀-òdì sí nígbà gbogbo.

6Nítorí náà àwọn ènìyàn mi yóò mọ orúkọ mi;

nítorí ní ọjọ́ náà, wọn yóò mọ̀

pé Èmi ni ó ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ rẹ̀.

Bẹ́ẹ̀ ni, Èmi ni.”

752.7: Ap 10.36; Ro 10.15; Ef 6.15.Báwo ni ó ṣe dára tó lórí òkè

ẹsẹ̀ àwọn tí ó mú ìhìnrere ayọ̀ wá,

tí wọ́n kéde àlàáfíà,

tí ó mú ìhìnrere wá,

tí ó kéde ìgbàlà,

tí ó sọ fún Sioni pé,

“Ọlọ́run rẹ ń jẹ ọba!”

8Tẹ́tí sílẹ̀! Àwọn olùṣọ́ rẹ gbé ohùn wọn sókè

wọ́n kígbe papọ̀ fún ayọ̀.

Nígbà tí Olúwa padà sí Sioni,

wọn yóò rí i pẹ̀lú ojú u wọn.

9Ẹ bú sí orin ayọ̀ papọ̀,

ẹ̀yin ahoro Jerusalẹmu,

nítorí Olúwa ti tu àwọn ènìyàn rẹ̀ nínú,

ó sì ti ra Jerusalẹmu padà.

1052.10: Lk 2.30; 3.6.Olúwa yóò ṣí apá mímọ́ rẹ̀ sílẹ̀

ní ojú gbogbo orílẹ̀-èdè,

àti gbogbo òpin ilẹ̀ ayé yóò rí

ìgbàlà Ọlọ́run wa.

1152.11: 2Kọ 6.17.Ẹ túká, ẹ túká, ẹ jáde kúrò níhìn-ín-yìí!

Ẹ má fọwọ́ kan ohun àìmọ́ kan!

Ẹ jáde kúrò nínú rẹ̀ kí ẹ sì di mímọ́,

ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé ohun èlò Olúwa.

12Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kì yóò yára kúrò

tàbí kí ẹ sáré lọ;

nítorí Olúwa ni yóò síwájú yín lọ,

Ọlọ́run Israẹli ni yóò sì ṣe ààbò lẹ́yìn ín yín.

Ìpọ́njú àti ògo ìránṣẹ́ náà

13Kíyèsi i, ìránṣẹ́ mi yóò hùwà ọlọ́gbọ́n;

òun ni a ó gbé sókè tí a ó sì gbéga

a ó sì gbé e lékè gidigidi.

14Gẹ́gẹ́ bí a ti rí ọ̀pọ̀lọpọ̀ tí wọ́n ń bu ọlá fún un—

ìwò ojú rẹ ni a ti bàjẹ́ kọjá ti ẹnikẹ́ni àti ìrísí rẹ̀ ní a ti bàjẹ́ kọjá ohun tí ènìyàn ń fẹ́.

1552.15: Ro 15.21.Bẹ́ẹ̀ ni yóò ṣe bomirin àwọn orílẹ̀-èdè ká,

àwọn ọba yóò sì pa ẹnu wọn mọ́ nítorí rẹ̀.

Nítorí ohun tí a kò sọ fún wọn, wọn yóò rí i,

àti ohun tí wọn kò tí ì gbọ́, ni yóò sì yé wọn.