ኢሳይያስ 13 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

ኢሳይያስ 13:1-22

በባቢሎን ላይ የተነገረ ትንቢት

1የአሞጽ ልጅ ኢሳይያስ ስለ ባቢሎን ያየው ንግር፤

2በተራቈተ ኰረብታ ዐናት ላይ ምልክት ስቀሉ፤

ድምፃችሁን ከፍ አድርጋችሁ ጩኹ፤

በመሳፍንቱም በር እንዲገቡ፣

በእጅ ምልክት ስጡ።

3በድል አድራጊነቴ ደስ የሚላቸውን ቅዱሳኔን አዝዛለሁ፤

ቍጣዬንም እንዲፈጽሙ፣

ተዋጊዎቼን ጠርቻለሁ።

4በተራሮች ላይ እንደ ብዙ ሕዝብ ድምፅ

የሚሰማውን ጩኸት አድምጡ፤

በመንግሥታትም መካከል፣

እንደ ተጨናነቀ ሕዝብ ድምፅ የሆነውን ውካታ ስሙ!

የሰራዊት ጌታ እግዚአብሔር

ሰራዊቱን ለጦርነት አሰልፏል።

5እግዚአብሔርና የቍጣው ጦር መሣሪያ፣

ምድሪቱን በሙሉ ለማጥፋት፣

ከሩቅ አገር፣

ከሰማያትም ዳርቻ መጥተዋል።

6የእግዚአብሔር ቀን ቀርቧልና አልቅሱ፤

ሁሉን ቻይ13፥6 ዕብራይስጡ ሻዳይ ይላል። ከሆነ አምላክ ዘንድ ጥፋት ይመጣልና።

7ስለዚህ እጆች ሁሉ ሽባ ይሆናሉ፤

የሰውም ሁሉ ልብ ይቀልጣል።

8ሽብር ይይዛቸዋል፤

ሥቃይና ጭንቀት ይደርስባቸዋል፤

ምጥ እንደ ያዛት ሴት ያምጣሉ፤

እርስ በርሳቸው በድንጋጤ ይተያያሉ፤

ፊታቸውም በፍርሀት ቀይ ይሆናል።

9እነሆ፤ የእግዚአብሔር ቀን ጨካኝ ነው፤

ምድርን ባድማ ሊያደርጋት፣

በውስጧም ያሉትን ኀጢአተኞች ሊያጠፋ፣

ከመዓትና ከብርቱ ቍጣ ጋር ይመጣል።

10የሰማይ ከዋክብትና ሰራዊታቸው፣

ብርሃን አይሰጡም፤

ፀሓይ ገና ከመውጣቷ ትጨልማለች፤

ጨረቃም ብርሃኗን አትሰጥም።

11ዓለምን ስለ ክፋቷ፣

ክፉዎችንም ስለ ኀጢአታቸው እቀጣለሁ፤

የትዕቢተኞችን እብሪት እሽራለሁ፤

የጨካኞችንም ጕራ አዋርዳለሁ።

12ሰውን ከነጠረ ወርቅ ይልቅ ውድ፣

ከኦፊርም ወርቅ ይበልጥ ብርቅ አደርጋለሁ።

13ስለዚህ በሰራዊት ጌታ በእግዚአብሔር መዓት፣

ቍጣው በሚነድድበት ቀን፣

ሰማያትን እነቀንቃለሁ፤

ምድርንም ከስፍራዋ አናውጣለሁ።

14እንደሚታደን ሚዳቋ፣

እረኛም እንደሌለው የበግ መንጋ፣

እያንዳንዱ ወደ ወገኑ ይመለሳል፣

እያንዳንዱም ወደ አገሩ ይሸሻል።

15የተማረከ ሁሉ ይወጋል፤

የተያዘም ሁሉ በሰይፍ ይወድቃል።

16ዐይናቸው እያየ ሕፃናታቸው ይጨፈጨፋሉ፤

ቤታቸው ይዘረፋል፤ ሚስቶቻቸው ይደፈራሉ።

17እነሆ፤ ለብር ደንታ የሌላቸውን፣

በወርቅም ደስ የማይሰኙትን፣

ሜዶናውያንን አስነሣባቸዋለሁ።

18ቀስታቸው ጐበዞችን ይፈጃል፤

ሕፃናትን አይምሩም፤

ዐይናቸውም ለልጆች አይራራም።

19የመንግሥታት ዕንቍ፣

የከለዳውያን13፥19 ወይም፣ ባቢሎናውያን ማለት ነው። ትምክሕት

የሆነችውን ባቢሎንን፣

እግዚአብሔር እንደ ሰዶምና እንደ ገሞራ ይገለብጣታል።

20በዘመናት ሁሉ የሚቀመጥባት አይኖርም፤

የሚቀመጥባትም የለም፤

ዐረብ በዚያ ድንኳኑን አይተክልም፤

እረኛም መንጋውን በዚያ አያሳርፍም።

21ነገር ግን የምድረ በዳ አራዊት በዚያ ይተኛሉ፤

ቀበሮዎች ቤቶቿን ይሞላሉ፤

ጕጕቶች በዚያ ይኖራሉ፤

በበረሓ ፍየል የሚመሰሉ አጋንንትም ይዛለሉበታል።

22ጅቦች በምሽጎቿ፣

ቀበሮዎችም በተዋቡ ቤተ መንግሥቶቿ ይጮኻሉ፤

ጊዜዋ ቀርቧል፤

ቀኗም አይራዘምም።

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Isaiah 13:1-22

Àsọtẹ́lẹ̀ lòdì sí Babeli

113.1–14.23: Isa 47; Jr 50–51; Hk 1–2.Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Babeli

èyí tí Isaiah ọmọ Amosi rí:

2Gbé àsíá sókè ní orí òkè gbẹrẹfu,

kígbe sí wọn, pè wọ́n

láti wọlé sí ẹnu-ọ̀nà àwọn ọlọ́lá.

3Mo ti pàṣẹ fún àwọn ẹni mímọ́ mi,

mo ti pe àwọn jagunjagun mi

láti gbé ìbínú mi jáde

àwọn tí ń yọ̀ nínú ìṣẹ́gun mi.

4Gbọ́ ohùn kan ní àwọn orí òkè,

gẹ́gẹ́ bí i ti ogunlọ́gọ̀ ènìyàn

Gbọ́ ìdàrúdàpọ̀ láàrín àwọn ìjọba,

gẹ́gẹ́ bí i ti ìkórajọ àwọn orílẹ̀-èdè!

Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti kó ogun rẹ̀ jọ

àwọn jagunjagun fún ogun.

5Wọ́n wá láti ọ̀nà jíjìn réré,

láti ìpẹ̀kun ọ̀run wá

Olúwa pẹ̀lú àwọn ohun ìjà ìbínú rẹ̀,

láti pa gbogbo orílẹ̀-èdè náà run.

6Ẹ hu, nítorí ọjọ́ Olúwa súnmọ́ tòsí,

yóò sì wá gẹ́gẹ́ bí ìparun láti ọ̀dọ̀ Alágbára jùlọ.

7Nítorí èyí, gbogbo ọwọ́ ni yóò rọ,

ọkàn ẹnìkọ̀ọ̀kan yóò rẹ̀wẹ̀sì.

8Ẹ̀rù yóò gbá wọn mú,

ìrora àti ìpayínkeke yóò dìwọ́n mú,

wọn yóò kérora gẹ́gẹ́ bí obìnrin tí ó ń rọbí.

Ẹnìkínní yóò wo ẹnìkejì rẹ̀ pẹ̀lú ìpayà

ojú wọn á sì gbinájẹ.

9Kíyèsi i, ọjọ́ Olúwa ń bọ̀

ọjọ́ búburú, pẹ̀lú ìbínú

àti ìrunú gbígbóná—

láti sọ ilẹ̀ náà dahoro,

àti láti pa àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ inú rẹ̀ run.

1013.10: Mt 24.29; Mk 13.24; If 6.12; 8.12.Àwọn ìràwọ̀ ojú ọ̀run àti ìkójọpọ̀ wọn

kò sì ní fi ìmọ́lẹ̀ wọn hàn.

Àṣẹ̀ṣẹ̀yọ oòrùn yóò di òkùnkùn

àti òṣùpá kò ní fi ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ hàn.

11Èmi yóò jẹ ayé ní ìyà nítorí ibi rẹ̀,

àwọn ìkà nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn.

Èmi yóò fi òpin sí gààrù àwọn agbéraga

èmi ó sì rẹ ìgbéraga àwọn aláìláàánú sílẹ̀.

12Èmi yóò jẹ́ kí ọkùnrin kí ó wọn

ju ojúlówóo wúrà lọ,

yóò sì ṣọ̀wọ́n ju wúrà Ofiri lọ.

13Nítorí náà èmi yóò jẹ́ kí àwọn ọ̀run kí ó wárìrì;

ayé yóò sì mì tìtì ní ibùjókòó rẹ̀

láti ọwọ́ ìbínú Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

ní ọjọ́ ìbínú gbígbóná rẹ.

14Gẹ́gẹ́ bí egbin tí à ń dọdẹ rẹ̀,

gẹ́gẹ́ bí àgùntàn tí kò ní olùṣọ́,

ọ̀kọ̀ọ̀kan yóò padà tọ àwọn ènìyàn rẹ̀ lọ,

ọ̀kọ̀ọ̀kan yóò sá padà sí ilẹ̀ abínibí i rẹ̀.

15Ẹnikẹ́ni tí a bá gbámú ni a ó wọ́ nílẹ̀ tuurutu,

gbogbo àwọn tí ọwọ́ bá tẹ̀ ni yóò ti ipa idà kú.

16Àwọn ọ̀dọ́mọdé wọn ni a ó fọ́ sí wẹ́wẹ́ níṣojú wọn,

gbogbo ilẹ̀ wọn ni a ó kó

àwọn aya wọn ni a ó sì bá dàpọ̀.

17Kíyèsi i, èmi yóò ru àwọn Media sókè sí wọn,

àwọn tí kò bìkítà fún fàdákà

tí kò sì ní inú dídùn sí wúrà.

18Ọrùn wọn yóò ré àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin lulẹ̀;

wọn kò ní ṣàánú àwọn ọ̀dọ́mọdé

tàbí kí wọn ṣíjú àánú wo àwọn ọmọdé.

19Babeli, ohun ọ̀ṣọ́ àwọn ìjọba

ògo ìgbéraga àwọn ará Babeli

ni Ọlọ́run yóò da ojú rẹ̀ bolẹ̀

gẹ́gẹ́ bí Sodomu àti Gomorra.

20A kì yóò tẹ̀ ibẹ̀ dó mọ́

tàbí kí á gbé inú rẹ̀ láti ìrandíran;

Ará Arabia kì yóò pa àgọ́ níbẹ̀ mọ́,

olùṣọ́-àgùntàn kan kì yóò kó ẹran rẹ̀ sinmi níbẹ̀.

2113.21: If 18.2.Ṣùgbọ́n àwọn ẹranko igbó ni yóò dùbúlẹ̀ níbẹ̀,

àwọn ajáko yóò kún inú ilé wọn,

níbẹ̀ ni àwọn òwìwí yóò máa gbé

níbẹ̀ ni àwọn ewúrẹ́ igbó yóò ti máa bẹ́ kiri.

22Ìkookò yóò máa gbó ní ibùba wọn,

àwọn ajáko nínú arẹwà ààfin wọn.