መዝሙር 40 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

መዝሙር 40:1-17

መዝሙር 40

የምስጋናና የርዳታ ልመና ጸሎት

40፥13-17 ተጓ ምብ – መዝ 70፥1-5

ለመዘምራን አለቃ፤ የዳዊት መዝሙር።

1እግዚአብሔርን ደጅ ጠናሁት፤

እርሱም ዘንበል አለልኝ፤ ጩኸቴንም ሰማ።

2ከሚውጥ ጕድጓድ፣

ከሚያዘቅጥ ማጥ አወጣኝ፤

እግሮቼን በዐለት ላይ አቆመ፤

አካሄዴንም አጸና።

3ለአምላካችን የሚሆን ውዳሴ፣

አዲስ ዝማሬን በአፌ ላይ አኖረ፤

ብዙዎች ያያሉ፤ ይፈራሉም፤

በእግዚአብሔር ይታመናሉ።

4እግዚአብሔርን መታመኛው ያደረገ፣

ወደ ትዕቢተኞች የማይመለከት፣

የሐሰት አማልክትን40፥4 ወይም ሐሰትን ወደሚከተሉት ተብሎ መተርጐም ይችላል። ወደሚከተሉት የማያይ

ሰው ብፁዕ ነው።

5እግዚአብሔር አምላኬ ሆይ፤

አንተ ያደረግኸው ድንቅ ነገር ብዙ ነው፤

ለእኛ ያቀድኸውን፣

ሊዘረዝርልህ የሚችል ማንም የለም፤

ላውራው ልናገረው ብል፣

ስፍር ቍጥር አይኖረውም።

6መሥዋዕትንና ቊርባንን አልፈለግህም፤

ጆሮዎቼን ግን ከፈትህ፤40፥6 ዕብራይስጡ ከዚህ ጋር ይስማማል፤ የሰብዓ ሊቃናት ትርጕም ግን፣ አካልን ግን አዘጋጀህልኝ ይላል።

የሚቃጠል መሥዋዕትን፣

የኀጢአትንም መሥዋዕት አልሻህም።

7እኔም እንዲህ አልሁ፤ “እነሆ፤ መጥቻለሁ፤

ስለ እኔ በመጽሐፍ ተጽፏል፤

8አምላኬ ሆይ፤ ፈቃድህን ላደርግ እሻለሁ፤

ሕግህም በልቤ ውስጥ አለ።”

9በታላቅ ጉባኤ ውስጥ ጽድቅን አበሠርሁ፤

እግዚአብሔር ሆይ፤ አንተ እንደምታውቀው፣

ከንፈሮቼን አልገጠምሁም።

10ጽድቅህን በልቤ አልሸሸግሁም፤

ታማኝነትህንና ማዳንህን እናገራለሁ፤

ምሕረትህንና እውነትህን፣

ከታላቅ ጉባኤ አልደበቅሁም።

11እግዚአብሔር ሆይ፤ ምሕረትህን አትንፈገኝ፤

ቸርነትህና እውነትህ ዘወትር ይጠብቁኝ፤

12ስፍር ቍጥር የሌለው ክፋት ከብቦኛልና፤

የኀጢአቴ ብዛት ስለ ያዘኝ ማየት ተስኖኛል፤

ከራሴ ጠጕር ይልቅ በዝቷል፤

ልቤም ከድቶኛል።

13እግዚአብሔር ሆይ፤ ታድነኝ ዘንድ ፈቃድህ ይሁን፤

እግዚአብሔር ሆይ፤ እኔን ለመርዳት ፍጠን።

14ነፍሴን ለመንጠቅ የሚፈልጉ

ይፈሩ፤ ይዋረዱም፤

ጕዳቴንም የሚሹ፣

ተዋርደው በመጡበት ይመለሱ።

15በእኔ ላይ፣ “ዕሠይ! ዕሠይ!” የሚሉ፣

በራሳቸው ዕፍረት ይደንግጡ።

16አንተን የሚፈልጉ ሁሉ ግን፣

ሐሤት ያድርጉ፤ በአንተም ደስ ይበላቸው፤

ዘወትር የአንተን ማዳን የሚወድዱ፣

እግዚአብሔር ከፍ ከፍ ይበል” ይበሉ።

17እኔ ድኻና ችግረኛ ነኝ፤

ጌታ ግን ያስብልኛል።

አንተ ረዳቴና አዳኜ ነህ፤

አምላኬ ሆይ፤ አትዘግይ።

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 40:1-17

Saamu 40

Fún adarí orin. Ti Dafidi. Saamu.

1Mo fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ dúró de Olúwa;

ó sì dẹtí sí mi, ó sì gbọ́ ẹkún mi.

2Ó fà mí yọ gòkè

láti inú ihò ìparun,

láti inú ẹrẹ̀ pọ̀tọ̀pọ́tọ̀,

ó sì fi ẹsẹ̀ mi lé orí àpáta,

ó sì jẹ́ kí ìgbésẹ̀ mi wà láìfòyà.

3Ó fi orin tuntun sí mi lẹ́nu,

àní orin ìyìn sí Ọlọ́run wa.

Ọ̀pọ̀ yóò rí i wọn yóò sì bẹ̀rù,

wọn yóò sì gbẹ́kẹ̀lé Olúwa.

4Ayọ̀ ni fún àwọn wọ̀n-ọn-nì

tí ó fi Olúwa ṣe ìgbẹ́kẹ̀lé wọn

tí wọn kò sì yípadà sí agbéraga,

tàbí àwọn tí ó yapa

lọ sí ọ̀dọ̀ ọlọ́run mìíràn.

5Olúwa Ọlọ́run mi, Ọ̀pọ̀lọpọ̀

ni àwọn iṣẹ́ ìyanu tí ìwọ ti ṣe.

Àwọn ohun tí ìwọ ti ṣètò sílẹ̀ fún wa;

ni ẹnikẹ́ni kò le kà wọ́n fún ọ lẹ́sẹẹsẹ

tí èmi yóò sì sọ̀rọ̀ wọn,

wọ́n ju ohun tí

ènìyàn le è kà lọ.

640.6-8: Hb 10.5-9.Ẹbọ àti ẹran ẹbọ ni ìwọ kò fẹ́,

ìwọ ti ṣí mi ní etí.

Ọrẹ ẹbọ sísun àti ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀

ni ìwọ kò béèrè.

7Nígbà náà ni mo wí pé,

“Èmi nìyí;

nínú ìwé kíká ni

a kọ ọ nípa tèmi wí pé.

8Mo ní inú dídùn

láti ṣe ìfẹ́ ẹ̀ rẹ,

ìwọ Ọlọ́run mi;

Òfin rẹ̀ ń bẹ ní àyà mi.”

9Èmi ti sọ ìròyìn ayọ̀ ti ìgbàlà

láàrín àwùjọ ńlá;

wò ó,

èmi kò pa ètè mi mọ́,

gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti mọ̀,

ìwọ Olúwa.

10Èmi kò fi ìrànlọ́wọ́ ìgbàlà sin ní àyà mi;

èmí ti sọ̀rọ̀ nípa òtítọ́ àti ìgbàlà rẹ.

Èmi kò sì pa ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti òtítọ́ rẹ̀ mọ́

kúrò láàrín àwọn ìjọ ńlá.

11Ìwọ má ṣe,

fa àánú rẹ tí ó rọ́nú

sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ mi; Olúwa

jẹ́ kí ìṣeun ìfẹ́ rẹ

àti òtítọ́ rẹ

kí ó máa pa mi mọ́

títí ayérayé.

12Nítorí pé àìníye ibi

ni ó yí mi káàkiri,

ẹ̀ṣẹ̀ mi sì dì mọ́ mi,

títí tí èmi kò fi ríran mọ́;

wọ́n pọ̀ ju irun orí mi lọ,

àti wí pé àyà mí ti kùnà.

1340.13-17: Sm 70.1-5.Jẹ́ kí ó wù ọ́,

ìwọ Olúwa,

láti gbà mí là;

Olúwa,

yára láti ràn mí lọ́wọ́.

14Gbogbo àwọn wọ̀n-ọn-nì

ni kí ojú kí ó tì

kí wọn kí ó sì dààmú

àwọn tí ń wá ọkàn mi

láti parun:

jẹ́ kí a lé wọn padà sẹ́yìn

kí a sì dójútì wọ́n,

àwọn tí ń wá ìpalára mi.

15Jẹ́ kí àwọn tí ó wí fún mi pé, “Háà! Háà!”

ó di ẹni à fi ọwọ́ rọ́ sẹ́yìn nítorí ìtìjú wọn.

16Jẹ́ kí gbogbo àwọn tí ń wá ọ

kí ó máa yọ̀

kí inú wọn sì máa dùn sí ọ;

kí gbogbo àwọn tí ó sì fẹ́ ìgbàlà rẹ

kí o máa wí nígbà gbogbo pé,

“Gbígbéga ni Olúwa!”

17Bí ó ṣe ti èmi ni,

tálákà àti aláìní ni èmi,

ṣùgbọ́n Olúwa ń ṣe ìrántí mi.

Ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ mi

àti ìgbàlà mi;

Má ṣe jẹ́ kí ó pẹ́,

ìwọ Ọlọ́run mi.