መዝሙር 39 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

መዝሙር 39:1-13

መዝሙር 39

ታላቅ እግዚአብሔር-ታናሽ ሰው

ለመዘምራን አለቃ፣ ለኤዶታም፤ የዳዊት መዝሙር።

1እኔ፣ “በአንደበቴ እንዳልበድል፣

መንገዴን እጠብቃለሁ፤

ክፉዎችም በእኔ ዘንድ እስካሉ ድረስ፣

ልጓም በአፌ አስገባለሁ” አልሁ።

2እንደ ዲዳ ዝም አልሁ፤

ለበጎ ነገር እንኳ አፌን ዘጋሁ፤

ሆኖም ጭንቀቴ ባሰ።

3ልቤ በውስጤ ጋለ፤

በማሰላስልበትም ጊዜ እሳቱ ነደደ፤

ከዚያም በአንደበቴ እንዲህ ተናገርሁ፤

4እግዚአብሔር ሆይ፤ የሕይወቴን ፍጻሜ፣

የዘመኔንም ቍጥር አስታውቀኝ፤

ዐላፊ ጠፊ መሆኑንም ልረዳ።

5እነሆ፤ ዘመኔን በስንዝር ለክተህ አስቀመጥህ፤

ዕድሜዬም በፊትህ እንደ ኢምንት ነው፤

በርግጥ የሰው ሁሉ ሕይወት ተን ነው። ሴላ

6“ሰው የጥላ ውልብታ ነው፤

በከንቱም ይታወካል፤

ለማን እንደሚሆን ሳያውቅ ሀብት ንብረት ያከማቻል።

7“ጌታ ሆይ፤ አሁንስ ወደ ማን ልመልከት?

ተስፋዬ በአንተ ላይ ነው።

8ከኀጢአቴ ሁሉ አድነኝ፤

የሰነፎች መሣለቂያ አታድርገኝ።

9ይህን ያደረግህ አንተ ነህና፣

ዝም እላለሁ፤ አፌንም አልከፍትም።

10ክንድህን አንሣልኝ፤

ከእጅህ ምት የተነሣ ደክሜአለሁ።

11ሰዎችን ስለ ኀጢአታቸው ለመቅጣት ትገሥጻቸዋለህ፤

ሀብታቸውንም ብል እንደ በላው ታደርጋለህ፤

በርግጥ ሰው ሁሉ ተን ብቻ ነው። ሴላ

12እግዚአብሔር ሆይ፤ ጸሎቴን ስማ፤

ጩኸቴን አድምጥ፤

ልቅሶዬንም ቸል አትበል፤

በአንተ ፊት እኔ መጻተኛ ነኝና፤

እንደ አባቶቼም እንግዳ ነኝ።

13ላለመመለስ ከመሰናበቴ በፊት፣

ዳግመኛ ደስ ይለኝ ዘንድ ዐይንህን ከላዬ አንሣ።”

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 39:1-13

Saamu 39

Fún adarí orin. Fún Jedutuni. Saamu Dafidi.

1Mo wí pé, “èmi yóò ṣọ́ ọ̀nà mi

kí èmi kí ó má fi ahọ́n mi ṣẹ̀;

èmi yóò fi ìjánu kó ara mi ní ẹnu

níwọ̀n ìgbà tí ènìyàn búburú bá ń bẹ ní iwájú mi.”

2Mo fi ìdákẹ́ ya odi;

mo tilẹ̀ pa ẹnu mi mọ́ kúrò nínú ọ̀rọ̀ rere;

ìbànújẹ́ mi sì pọ̀ sí i.

3Àyà mi gbóná ní inú mi.

Nígbà tí mo ń ṣàṣàrò, iná ràn;

nígbà náà ni mo fi ahọ́n mi sọ̀rọ̀:

4Olúwa, jẹ́ kí èmi kí ó mọ òpin mi,

àti ìwọ̀n ọjọ́ mi, bí ó ti rí

kí èmi kí o le mọ ìgbà tí mó ní níhìn-ín.

5Ìwọ ti ṣe ayé mi

bí ìbú àtẹ́lẹwọ́,

ọjọ́ orí mi sì dàbí asán

ní iwájú rẹ:

Dájúdájú olúkúlùkù ènìyàn nínú

ìjókòó rere rẹ̀ jásí asán pátápátá. Sela.

6“Nítòótọ́ ni olúkúlùkù ń rìn kiri bí òjìji.

Nítòótọ́ ni wọ́n ń yọ ara wọn lẹ́nu lórí asán;

wọ́n ń kó ọrọ̀ jọ,

wọn kò sì mọ ẹni tí yóò ko lọ.

7“Ṣùgbọ́n ní ìsinsin yìí,

Olúwa,

kín ni mo ń dúró dè?

Ìrètí mí ń bẹ ní ọ̀dọ̀ rẹ.

8Gbà mí lọ́wọ́ ìrékọjá mi gbogbo.

Kí o má sì sọ mí di ẹni ẹ̀gàn

àwọn ènìyàn búburú.

9Mo dákẹ́ jẹ́ẹ́;

èmi kò sì ya ẹnu mi,

nítorí wí pé ìwọ ni ó ṣe é.

10Mú pàṣán rẹ kúrò ní ara mi;

èmí ṣègbé tán nípa lílù ọwọ́ rẹ.

11Ìwọ fi ìbáwí kìlọ̀

fún ènìyàn nítorí ẹ̀ṣẹ̀,

ìwọ a mú ẹwà rẹ parun

bí kòkòrò aṣọ;

nítòótọ́ asán ni ènìyàn gbogbo.

12“Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa,

kí o sì fetí sí igbe mi;

kí o má ṣe di etí rẹ sí ẹkún mi

nítorí àlejò ni èmi lọ́dọ̀ rẹ

àti àtìpó, bí gbogbo àwọn baba mi ti rí.

13Dá mi sí, kí èmi lè ní agbára,

kí èmi tó lọ kúrò níhìn-ín yìí,

àti kí èmi ó tó ṣe aláìsí.”