መዝሙር 16 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

መዝሙር 16:1-11

መዝሙር 16

እግዚአብሔር ርስቴ

የዳዊት ቅኔ።

1አምላክ ሆይ፤ መጠጊያዬ ነህና፣

በከለላህ ሰውረኝ።

2እግዚአብሔርን፣ “አንተ ጌታዬ ነህ፤

ከአንተ በቀር በጎነት የለኝም”

አልሁት።

3በምድር ያሉ ቅዱሳን፣

ሙሉ ደስታ የማገኝባቸው ክቡራን ናቸው።16፥3 ወይም በምድሪቱ ላሉ አረማውያን፣ ካህናትና ደስ ለተሰኙባቸው መኳንንት ሁሉ ይህን እላለሁ

4ሌሎችን አማልክት የሚከተሉ፣

ሐዘናቸው ይበዛል፤

እኔ ግን የደም ቍርባናቸውን አላፈስስም፤

ስማቸውንም በአፌ አልጠራም፤

5እግዚአብሔር የርስት ድርሻዬና ጽዋዬ ነው፤

ዕጣዬም በእጅህ ናት።

6መካለያ ገመድ ባማረ ስፍራ ተጥሎልኛል፤

በርግጥም የተዋበች ርስት አግኝቻለሁ።

7የሚመክረኝን እግዚአብሔርን እባርካለሁ፤

በሌሊት እንኳ ልቤ ቀናውን ያመላክተኛል።

8እግዚአብሔርን ሁልጊዜ በፊቴ አድርጌአለሁ፤

እርሱ በቀኜ ስላለ አልናወጥም።

9ስለዚህ ልቤ ደስ አለው፤ ነፍሴም ሐሤት አደረገች፤

ሥጋዬም ያለ ሥጋት ዐርፎ ይቀመጣል፤

10በሲኦል16፥10 ወይም በመቃብር ውስጥ አትተወኝምና፤

ቅዱስህም16፥10 ወይም በአንተ የታመነውን መበስበስን እንዲያይ አታደርግም።

11የሕይወትን መንገድ ታሳየኛለህ፤16፥11 ወይም ታሳውቀኛለህ

በአንተ ዘንድ የደስታ ሙላት፣

በቀኝህም የዘላለም ፍሥሓ አለ።

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 16:1-11

Saamu 16

Miktamu ti Dafidi.

1Pa mí mọ́, Ọlọ́run,

nítorí nínú rẹ ni ààbò mi wà.

2Mo sọ fún Olúwa, “ìwọ ni Olúwa mi,

lẹ́yìn rẹ èmi kò ní ìre kan.”

3Sí àwọn ènìyàn tí ó wà ní ayé,

àwọn ni ológo nínú èyí tí ayọ̀ mí wà.

4Ìṣòro àwọn wọ̀n-ọn-nì yóò pọ̀ sí i, àní àwọn tí ń tọ ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn.

Ẹbọ ohun mímu ẹ̀jẹ̀ wọn ni èmi kì yóò ta sílẹ̀,

bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò dá orúkọ wọn lẹ́nu mi.

5Olúwa, ni ìpín ìní mi tí mo yàn àti ago mi,

ó ti pa ohun tí í ṣe tèmi mọ́.

6Okùn ààlà ilẹ̀ ti bọ́ sí ọ̀dọ̀ mi ní ibi dídára;

nítòótọ́ mo ti ní ogún rere.

7Èmi yóò yin Olúwa, ẹni tí ó gbà mí ní ìyànjú;

ní òru, ọkàn mí ń bá mi sọ̀rọ̀.

816.8-11: Ap 2.25-28,31.Mo ti gbé Ọlọ́run síwájú mi ní ìgbà gbogbo.

Nítorí tí ó wà ní ọwọ́ ọ̀tún mi, a kì yóò mì mí.

9Nítorí èyí, ọkàn mi yọ̀, ahọ́n mi pẹ̀lú ń fò fáyọ̀;

ara mi pẹ̀lú yóò sinmi ní ààbò,

1016.10: Ap 13.35.nítorí ìwọ kò ní fi ọ̀kan sílẹ̀ nínú isà òkú,

tàbí kí ìwọ jẹ́ kí ẹni mímọ́ rẹ kí ó rí ìdíbàjẹ́.

11Ìwọ ti fi ipa ọ̀nà ìyè hàn mí;

Ìwọ yóò kún mi pẹ̀lú ayọ̀ ní iwájú rẹ,

pẹ̀lú ìdùnnú ayérayé ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ.