De qui tout dépend
1Cantique pour la route vers la demeure de l’Eternel127.1 Voir note 120.1.. De Salomon.
Si l’Eternel ╵ne bâtit la maison,
en vain les bâtisseurs travaillent.
Si l’Eternel ╵ne garde pas la ville,
en vain la sentinelle veille.
2Oui, il est vain ╵de vous lever très tôt ╵et de vous coucher tard,
et de vous donner tant de peine ╵pour gagner votre pain.
Car Dieu en donne autant ╵à ceux qui lui sont chers ╵pendant qu’ils dorment.
3Des fils : ╵voilà le patrimoine ╵que donne l’Eternel,
oui, des enfants ╵sont une récompense.
4Ils sont pareils aux flèches ╵dans la main d’un guerrier,
les fils de la jeunesse127.4 Nés alors que les parents étaient encore jeunes et qui pourront donc les assister (v. 5) lorsqu’ils seront âgés..
5Heureux est l’homme ╵dont le carquois en est rempli !
Il ne connaîtra pas la honte
lorsqu’il entrera en contestation ╵avec son adversaire ╵aux portes de la ville127.5 Là où se traitaient les affaires et où l’on exerçait la justice..
Saamu 127
Orin fún ìgòkè. Ti Solomoni.
1Bí kò ṣe pé Olúwa bá kọ́ ilé náà
àwọn tí ń kọ́ ọ ń ṣiṣẹ́ lásán ni;
bí kò ṣe pé Olúwa bá pa ìlú mọ́, olùṣọ́ jí lásán.
2Asán ni fún ẹ̀yin ti ẹ dìde ní kùtùkùtù
láti pẹ́ dùbúlẹ̀, láti jẹ oúnjẹ làálàá;
bẹ́ẹ̀ ni ó ń fi ìre fún olùfẹ́ rẹ̀ lójú ọ̀run.
3Kíyèsi i, àwọn ọmọ ni ìní Olúwa:
ọmọ inú sì ni èrè rẹ̀.
4Bí ọfà ti rí ní ọwọ́ alágbára,
bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ èwe
5Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà tí apó rẹ̀ kún fún wọn;
ojú kì yóò tì wọ́n,
ṣùgbọ́n wọn yóò ṣẹ́gun àwọn ọ̀tá ní ẹnu-ọ̀nà.