Psaumes 126 – BDS & YCB

La Bible du Semeur

Psaumes 126:1-6

Semailles et moisson

1Cantique pour la route vers la demeure de l’Eternel126.1 Voir note 120.1..

Quand l’Eternel a ramené ╵les captifs de Sion126.1 Autre traduction : a changé le sort de Sion.,

nous étions comme dans un rêve.

2Alors nous ne cessions de rire

et de pousser des cris de joie.

Alors on disait chez les autres peuples :

« Oh, l’Eternel a fait pour eux ╵de grandes choses ! »

3Oui, l’Eternel a fait pour nous

de grandes choses :

nous sommes dans la joie.

4Viens changer notre sort126.4 Autre traduction : ramène nos captifs., ╵ô Eternel,

comme quand l’eau coule à nouveau ╵dans les lits des rivières du Néguev.

5Qui sème dans les larmes

moissonnera avec des cris de joie !

6Qui s’en va en pleurant ╵alors qu’il porte sa semence

reviendra en poussant des cris de joie, ╵alors qu’il portera ses gerbes.

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 126:1-6

Saamu 126

Orin fún ìgòkè.

1Nígbà tí Olúwa mú ìkólọ Sioni padà,

àwa dàbí ẹni tí ó ń lá àlá.

2Nígbà náà ni ẹnu wa kún fún ẹ̀rín,

àti ahọ́n wa kọ orin;

nígbà náà ni wọ́n wí nínú àwọn kèfèrí pé,

Olúwa ṣe ohun ńlá fún wọn.

3Olúwa ṣe ohun ńlá fún wa;

nítorí náà àwa ń yọ̀.

4Olúwa mú ìkólọ wa padà,

bí ìṣàn omi ní gúúsù.

5Àwọn tí ń fi omijé fún irúgbìn

yóò fi ayọ̀ ka.

6Ẹni tí ń fi ẹkún rìn lọ,

tí ó sì gbé irúgbìn lọ́wọ́,

lóòtítọ́, yóò fi ayọ̀ padà wá,

yóò sì ru ìtí rẹ̀.