Saamu 9
Fún adarí orin. Ní ti ohun orin “Ní ti ikú ọmọ.” Saamu ti Dafidi.
1Èmi ó yìn ọ́, Olúwa, pẹ̀lú gbogbo ọkàn mi;
Èmi ó sọ ti ìyanu rẹ gbogbo.
2Inú mi yóò dùn, èmi yóò sì yọ̀ nínú rẹ;
Èmi ó kọrin ìyìn sí orúkọ rẹ, Ìwọ Ọ̀gá-Ògo jùlọ.
3Àwọn ọ̀tá mi pẹ̀yìndà;
Wọ́n kọsẹ̀ wọn sì ṣègbé níwájú rẹ.
4Nítorí ìwọ ti di òtítọ́ àti ọ̀ràn mi mú;
ìwọ ti jókòó lórí ìtẹ́ rẹ, láti ṣe ìdájọ́ òdodo.
5Ìwọ ti bá orílẹ̀-èdè wí, Ìwọ sì ti pa ẹni búburú run;
Ìwọ ti yọ orúkọ wọn kúrò láé àti láéláé.
6Ìparun àìlópin ti borí àwọn ọ̀tá,
Ìwọ ti fa àwọn ìlú wọn tu;
àní ìrántí wọn sì ti ṣègbé.
7Olúwa jẹ ọba títí láé;
ó ti gbé ìtẹ́ rẹ̀ kalẹ̀ fún ìdájọ́.
89.8: Ap 17.31.Òun yóò sì ṣe ìdájọ́ ayé ní òdodo;
yóò ṣe àkóso ènìyàn pẹ̀lú òdodo.
9Olúwa ni ààbò fún àwọn tí a ni lára,
ibi ìsádi ní àkókò ìpọ́njú.
10Àwọn tí ó mọ orúkọ rẹ yóò gbẹ́kẹ̀lé ọ,
nítorí, Olúwa, kò kọ àwọn tó ń wá a sílẹ̀.
11Kọ orin ìyìn sí Olúwa, tí o ń jẹ ọba ní Sioni;
kéde láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ohun tí ó ṣe.
12Nítorí ẹni tí ó ń gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ rántí;
òun kò kọ ẹkún àwọn tí a pọ́n lójú.
13Olúwa, wo bí àwọn ọ̀tá ṣe ń ṣe inúnibíni sí mi!
Ṣàánú, kí o sì gbé mí sókè kúrò ní ẹnu-ọ̀nà ikú,
14Kí èmi kí ó lè sọ ti ìyìn rẹ
ni ẹnu-ọ̀nà àwọn ọmọbìnrin Sioni
àti láti máa yọ̀ nínú ìgbàlà rẹ.
15Àwọn orílẹ̀-èdè ti jì sí kòtò tí wọn ti gbẹ́;
ẹsẹ̀ wọn ni àwọ̀n tí wọ́n dẹ sílẹ̀ kọ́.
16A mọ Olúwa nípa òdodo rẹ̀;
àwọn ènìyàn búburú ni a dẹ́kun mú nípa iṣẹ́ ọwọ́ wọn.
17Àwọn ènìyàn búburú ni a ó dà sí isà òkú,
àti gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó gbàgbé Ọlọ́run.
18Ṣùgbọ́n àwọn aláìní ni a kò ní gbàgbé láéláé,
ìrètí àwọn ti ó tálákà ni a kì yóò gbàgbé láéláé.
19Dìde, Olúwa, má ṣe jẹ́ kí ènìyàn borí;
Jẹ́ kí a ṣe ìdájọ́ àwọn orílẹ̀-èdè ni iwájú rẹ.
20Lù wọ́n pẹ̀lú ìpayà, Olúwa;
jẹ́ kí àwọn orílẹ̀-èdè mọ̀ pé ènìyàn lásán ni wọ́n. Sela.
Salmo 99 Os salmos 9 e 10 talvez tenham sido originalmente um único poema, organizado em ordem alfabética, no hebraico. Na Septuaginta constituem um único salmo.
Para o mestre de música. De acordo com muth-laben9.0 Expressão de sentido desconhecido. Tradicionalmente: De acordo com a melodia A Morte para o Filho.. Salmo davídico.
1Senhor, quero dar-te graças de todo o coração
e falar de todas as tuas maravilhas.
2Em ti quero alegrar-me e exultar,
e cantar louvores ao teu nome, ó Altíssimo.
3Quando os meus inimigos contigo se defrontam,
tropeçam e são destruídos.
4Pois defendeste o meu direito e a minha causa;
em teu trono te assentaste,
julgando com justiça.
5Repreendeste as nações e destruíste os ímpios;
para todo o sempre apagaste o nome deles.
6O inimigo foi totalmente arrasado, para sempre;
desarraigaste as suas cidades;
já não há quem delas se lembre.
7O Senhor reina para sempre;
estabeleceu o seu trono para julgar.
8Ele mesmo julga o mundo com justiça;
governa os povos com retidão.
9O Senhor é refúgio para os oprimidos,
uma torre segura na hora da adversidade.
10Os que conhecem o teu nome confiam em ti,
pois tu, Senhor, jamais abandonas os que te buscam.
11Cantem louvores ao Senhor, que reina em Sião;
proclamem entre as nações os seus feitos.
12Aquele que pede contas do sangue derramado não esquece;
ele não ignora o clamor dos oprimidos.
13Misericórdia, Senhor!
Vê o sofrimento que me causam os que me odeiam.
Salva-me das portas da morte,
14para que, junto às portas da cidade9.14 Hebraico: filha. de Sião,
eu cante louvores a ti
e ali exulte em tua salvação.
15Caíram as nações na cova que abriram;
os seus pés ficaram presos no laço que esconderam.
16O Senhor é conhecido pela justiça que executa;
os ímpios caem em suas próprias armadilhas. Interlúdio9.16 Hebraico: Higaion.. Pausa
17Voltem os ímpios ao pó9.17 Hebraico: Sheol. Essa palavra também pode ser traduzida por sepultura, profundezas ou morte.,
todas as nações que se esquecem de Deus!
18Mas os pobres nunca serão esquecidos,
nem se frustrará a esperança dos necessitados.
19Levanta-te, Senhor!
Não permitas que o mortal triunfe!
Julgadas sejam as nações na tua presença.
20Infunde-lhes terror, Senhor;
saibam as nações que não passam de seres humanos. Pausa