Matiu 2 – YCB & GKY

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Matiu 2:1-23

Ìbẹ̀wò àwọn amòye

12.1: Lk 2.4-7; 1.5.Lẹ́yìn ìgbà tí a bí Jesu ní Bẹtilẹhẹmu ti Judea, ni àkókò ọba Herodu, àwọn amòye ti ìlà-oòrùn wá sí Jerusalẹmu. 22.2: Jr 23.5; Sk 9.9; Mk 15.2; Jh 1.49; Nu 24.17.Wọ́n si béèrè pé, “Níbo ni ẹni náà tí a bí tí í ṣe ọba àwọn Júù wà? Àwa ti rí ìràwọ̀ rẹ̀ ní ìlà-oòrùn, a sì wá láti foríbalẹ̀ fún un.”

3Nígbà tí ọba Herodu sì gbọ́ èyí, ìdààmú bá a àti gbogbo àwọn ara Jerusalẹmu pẹ̀lú rẹ̀ 4Nígbà tí ó sì pe àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin jọ, ó bi wọ́n léèrè níbi ti a ó gbé bí Kristi? 52.5: Jh 7.42.Wọ́n sì wí pé, “Ní Bẹtilẹhẹmu ti Judea, èyí ni ohun tí wòlíì ti kọ ìwé rẹ̀ pé:

62.6: Mik 5.2.“ ‘Ṣùgbọ́n ìwọ Bẹtilẹhẹmu, ní ilẹ̀ Judea,

ìwọ kò kéré jù láàrín àwọn ọmọ-aládé Juda;

nítorí láti inú rẹ ni Baálẹ̀ kan yóò ti jáde,

Ẹni ti yóò ṣe ìtọ́jú Israẹli, àwọn ènìyàn mi.’ ”

7Nígbà náà ni Herodu ọba pe àwọn amòye náà sí ìkọ̀kọ̀, ó sì wádìí ni ọwọ́ wọn, àkókò náà gan an tí wọ́n kọ́kọ́ rí ìràwọ̀. 8Ó sì rán wọn lọ sí Bẹtilẹhẹmu, ó sì wí pé, “Ẹ lọ ṣe ìwádìí fínní fínní ní ti ọmọ náà tí a bí. Lẹ́yìn tí ẹ bá sì rí i, ẹ padà wá sọ fún mi, kí èmi náà le lọ foríbalẹ̀ fún un.”

9Nígbà tí wọ́n sì gbọ́ ọ̀rọ̀ ọba, wọ́n mú ọ̀nà wọn pọ̀n, sì wò ó, ìràwọ̀ tí wọ́n ti rí láti ìhà ìlà-oòrùn wá, ó ṣáájú wọn, títí tí ó fi dúró lókè ibi tí ọmọ náà gbé wà. 10Nígbà tí wọ́n sì rí ìràwọ̀ náà, ayọ̀ kún ọkàn wọn. 112.11: Mt 1.18; 12.46.Bí wọ́n tí wọ inú ilé náà, wọn rí ọmọ ọwọ́ náà pẹ̀lú Maria ìyá rẹ̀, wọ́n wólẹ̀, wọ́n foríbalẹ̀ fún un. Nígbà náà ni wọ́n tú ìṣúra wọn, wọ́n sì ta Jesu lọ́rẹ: wúrà, tùràrí àti òjìá. 122.12: Mt 2.22; Ap 10.22; Hb 11.7.Nítorí pé Ọlọ́run ti kìlọ̀ fún wọn ní ojú àlá pé kí wọ́n má ṣe padà tọ Herodu lọ mọ́, wọ́n gba ọ̀nà mìíràn lọ sí ìlú wọn.

A gbé Jesu sálọ sì Ejibiti

13Nígbà tí wọn ti lọ, angẹli Olúwa fi ara hàn Josẹfu ní ojú àlá pé, “Dìde, gbé ọmọ ọwọ́ náà àti ìyá rẹ̀, kí ó sì sálọ sí Ejibiti. Dúró níbẹ̀ títí tí èmi yóò fi sọ fún ọ, nítorí Herodu yóò wá ọ̀nà láti pa ọmọ ọwọ́ náà.”

14Nígbà náà ni ó sì dìde, ó mú ọmọ ọwọ́ náà àti ìyá rẹ̀ ní òru, ó sì lọ sí Ejibiti, 152.15: Ho 11.1.ó sì wà níbẹ̀ títí tí Herodu fi kú. Èyí jẹ́ ìmúṣẹ àsọtẹ́lẹ̀ ohun tí Olúwa sọ láti ẹnu wòlíì pé: “Mo pe ọmọ mi jáde láti Ejibiti wá.”

16Nígbà tí Herodu rí í pé àwọn amòye náà ti tan òun jẹ, ó bínú gidigidi, ó sì pàṣẹ kí a pa gbogbo àwọn ọmọkùnrin tí ó wà ní Bẹtilẹhẹmu àti ní ẹkùn rẹ̀ láti àwọn ọmọ ọdún méjì sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bi àkókò tí ó ti fi ẹ̀sọ̀ ẹ̀sọ̀ béèrè lọ́wọ́ àwọn amòye náà. 17Nígbà náà ni èyí tí a ti sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu wòlíì Jeremiah wá ṣẹ pé:

182.18: Jr 31.15.“A gbọ́ ohùn kan ní Rama,

ohùn réré ẹkún àti ọ̀fọ̀ ńlá,

Rakeli ń sọkún àwọn ọmọ rẹ̀.

Ó kọ̀ láti gbìpẹ̀

nítorí àwọn ọmọ rẹ̀ kò sí mọ́.”

Ìpadà sí Nasareti

192.19: Mt 1.20; 2.13.Lẹ́yìn ikú Herodu, angẹli Olúwa fi ara hàn Josẹfu lójú àlá ní Ejibiti 20Ó sì wí fún un pé, “Dìde gbé ọmọ ọwọ́ náà àti ìyá rẹ̀ padà sí ilẹ̀ Israẹli, nítorí àwọn tí ń wá ẹ̀mí ọmọ ọwọ́ náà láti pa ti kú.”

21Nítorí náà, o sì dìde, ó gbé ọmọ ọwọ́ náà àti ìyá rẹ̀ ó sì wá sí ilẹ̀ Israẹli. 22Ṣùgbọ́n nígbà tí ó gbọ́ pé Akelausi ni ó ń jẹ ọba ní Judea ní ipò Herodu baba rẹ̀, ó bẹ̀rù láti lọ sí ì bẹ̀. Nítorí tí Ọlọ́run ti kìlọ̀ fún un ní ojú àlá, ó yí padà, ó sì gba ẹkùn Galili lọ, 232.23: Lk 1.26; Mk 1.24.ó sì lọ í gbé ní ìlú tí a pè ní Nasareti. Nígbà náà ni èyí tí a sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu àwọn wòlíì wá sí ìmúṣẹ: “A ó pè é ní ará Nasareti.”

Holy Bible in Gĩkũyũ

Mathayo 2:1-23

Gũceererwo nĩ Andũ Oogĩ-a-Njata

12:1 Luk 2:4-7Na rĩrĩ, thuutha wa Jesũ gũciarwo kũu itũũra-inĩ rĩa Bethilehemu bũrũri wa Judea, hĩndĩ ya mũthamaki wetagwo Herode, andũ Oogĩ-a-Njata moimĩte irathĩro magĩũka Jerusalemu, 22:2 Joh 1:49; Ndar 24:17makĩũria atĩrĩ, “Ũrĩa ũciarĩtwo arĩ mũthamaki wa Ayahudi-rĩ, arĩ ha? Nĩtuonire njata yake mwena wa irathĩro, na nĩtũũkĩte kũmũhooya.”

3Rĩrĩa Mũthamaki Herode aiguire ũguo, agĩtangĩka ngoro, o hamwe na andũ Jerusalemu othe. 4Na aarĩkia gwĩta athĩnjĩri-Ngai2:4 Athĩnjĩri-Ngai maarĩ atongoria a mahooya ma Ayahudi, na nĩo maarutagĩra Ngai magongona. arĩa anene othe, na arutani a watho hamwe, akĩmooria kũrĩa Kristũ aarĩ aciarĩrwo. 52:5 Joh 7:42Makĩmũcookeria atĩrĩ, “Nĩ Bethilehemu, bũrũri wa Judea, nĩgũkorwo nĩ kwandĩkĩtwo nĩ mũnabii, akoiga atĩrĩ:

62:6 Mik 5:2“ ‘Nawe Bethilehemu, kũu bũrũri wa Juda,

tiwe ũrĩa mũnini mũno wa aathani a Juda;

tondũ thĩinĩ waku nĩgũkoima ũrĩa ũgaathanaga,

ũrĩa ũgaatuĩka mũrĩithi wa andũ akwa a Isiraeli.’ ”

7Nake Herode agĩĩta andũ acio Oogĩ-a-Njata na hitho, na agĩtuĩria kuuma kũrĩ o ihinda rĩrĩa njata ĩyo yoonekete. 8Akĩmatũma Bethilehemu akĩmeera atĩrĩ, “Thiĩi mũgatuĩrie wega ũhoro wa kaana kau. Mwarĩkia gũkoona mũũke mũũmenyithie, nĩgeetha o na niĩ thiĩ ngagaturĩrie ndu ndĩkahooe.”

9Nao maarĩkia kũigua ciugo cia mũthamaki magĩthiĩ, nayo njata ĩrĩa moonete irathĩro ĩkĩmatongoria nginya ĩkĩrũgama igũrũ rĩa harĩa kaana kau kaarĩ. 10Rĩrĩa moonire njata ĩyo, magĩkena gĩkeno kĩnene mũno. 112:11 Isa 60:3; Thab 72:10Nao magĩtoonya nyũmba, na makĩona kaana karĩ na nyina Mariamu, magĩkainamĩrĩra, magĩkahooya. Magĩcooka makĩohora indo ciao cia goro, magĩkahe iheo cia thahabu, na ũbumba, na manemane.2:11 Ũbumba nĩ mahuti manungi wega macinagwo na mwaki. Manemane nĩ indo ithondekagwo na kĩndũ kĩhaana ta ũũkĩ wa gĩthaka, inungaga wega na nĩ cia goro mũno. 122:12 Ahib 11:7; Math 27:19Na nĩ ũndũ wa gũkaanio na kĩroto matigacookere kwa Herode, magĩcooka bũrũri wao magereire njĩra ĩngĩ.

Kũũrĩra Bũrũri wa Misiri

132:13 Atũm 5:19; Math 27:19; Kũg 12:4Maarĩkia gũthiĩ-rĩ, mũraika wa Mwathani akiumĩrĩra Jusufu kĩroto-inĩ, akĩmwĩra atĩrĩ, “Ũkĩra woe kaana gaka na nyina mũũrĩre Misiri. Ikarai kũu nginya rĩrĩa ngaakwĩra, nĩgũkorwo Herode nĩegũcaria kaana kau akoorage.”

14Nĩ ũndũ ũcio-rĩ, agĩũkĩra, akĩoya kaana na nyina ũtukũ, magĩthiĩ Misiri, 152:15 Hos 11:1; Thaam 4:22, 23kũrĩa maikarire nginya rĩrĩa Herode aakuire. Na nĩ ũndũ ũcio, ũhoro ũrĩa Mwathani oigĩte na kanua ka mũnabii ũkĩhinga, rĩrĩa oigire atĩrĩ, “Ndeetire mũrũ wakwa oime bũrũri wa Misiri.”

16Hĩndĩ ĩrĩa Herode aamenyire atĩ nĩaheenirio nĩ Oogĩ-a-Njata, akĩrakara mũno, akĩruta watho wa kũũraga tũhĩĩ tuothe kũu Bethilehemu na kũrĩa gũkuhĩ nakuo, tũrĩa twarĩ na ũkũrũ wa mĩaka ĩĩrĩ gũcooka na thĩ, kũringana na ihinda rĩrĩa eerĩtwo nĩ Oogĩ-a-Njata. 172:17 Math 1:22Hĩndĩ ĩyo ũhoro ũrĩa waarĩtio na kanua ka mũnabii Jeremia ũkĩhinga, rĩrĩa oigire atĩrĩ:

182:18 Jer 31:15; Kĩam 35:19“Mũgambo nĩwaiguirwo kũu Rama,

kĩrĩro na gũcakaya kũnene,

Rakeli akĩrĩrĩra ciana ciake,

na akarega kũhoorerio, tondũ itirĩ ho.”

Gũcooka Nazarethi

192:19 Atũm 5:19; Math 27:19Na rĩrĩ, Herode akua-rĩ, mũraika wa Mwathani akiumĩrĩra Jusufu kĩroto-inĩ kũu Misiri, 20akĩmwĩra atĩrĩ, “Ũkĩra, woe kaana gaka na nyina, mũthiĩ bũrũri wa Isiraeli, nĩgũkorwo arĩa maageragia gũkooraga nĩmakuĩte.”

21Nĩ ũndũ ũcio, agĩũkĩra, akĩoya kaana na nyina, magĩthiĩ bũrũri wa Isiraeli. 222:22 Math 2:12, 13, 19; Luk 2:39Rĩrĩa aiguire atĩ Arikelau nĩwe wathamakaga Judea handũ ha ithe Herode, agĩĩtigĩra gũthiĩ kuo. Na aarĩkia gũkaanio kĩroto-inĩ-rĩ, agĩthiĩ bũrũri wa Galili, 232:23 Mar 1:24; Joh 1:45-46; Luk 1:13, 57-66agĩthiĩ gũtũũra itũũra rĩĩtagwo Nazarethi. Nĩ ũndũ ũcio ũhoro ũrĩa waarĩtio na tũnua twa anabii ũkĩhinga, rĩrĩa moigire atĩrĩ, “Nĩageetagwo Mũnazari.”