Heberu 2 – YCB & GKY

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Heberu 2:1-18

Ìkìlọ̀ láti ṣe ìgbọ́ràn

1Nítorí náà, ó yẹ kí àwa máa fi iyè sí àwọn nǹkan wọ̀n-ọn-nì gidigidi tí àwa ti gbọ́, kí a má ba à gbá wa lọ kúrò nínú wọn nígbà kan. 2Nítorí bí ọ̀rọ̀ tí a tí ẹnu àwọn angẹli sọ bá sì dúró ṣinṣin, àti tí olúkúlùkù ẹ̀ṣẹ̀ sí òfin àti àìgbọ́ràn gba ìjìyà tí ó tọ́ sí i, 3kín ni ohun náà tí ó mú wa lérò pé a lè bọ́ kúrò nínú ìjìyà bí a kò bá náání ìgbàlà ńlá yìí? Ìgbàlà tí Olúwa fúnrarẹ̀ kọ́kọ́ kéde, èyí tí a sì fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ fún wa láti ọwọ́ àwọn tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ náà lẹ́nu rẹ̀. 4Ọlọ́run jẹ́rìí sí i nípa àwọn iṣẹ́ ààmì àti ìyanu àti oríṣìíríṣìí iṣẹ́ agbára àti nípa ẹ̀bùn Ẹ̀mí Mímọ́ tí a pín gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ̀.

Jesu bí arákùnrin rẹ̀

5Nítorí pé, kì í ṣe abẹ́ ìṣàkóso àwọn angẹli ni ó fi ayé tí ń bọ̀, tí àwa ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ sí. 62.6-9: Sm 8.4-6.Ṣùgbọ́n ibìkan wà tí ẹnìkan tí jẹ́rìí pé:

“Kí ni ènìyàn tí ìwọ fi ń ṣe ìrántí rẹ̀,

tàbí ọmọ ènìyàn, tí ìwọ fi ń bẹ̀ ẹ́ wò?

7Ìwọ dá a ní onírẹ̀lẹ̀ díẹ̀ ju àwọn angẹli lọ;

ìwọ fi ògo àti ọlá de e ni adé,

ìwọ sì fi í jẹ olórí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ:

8Ìwọ fi ohun gbogbo sábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀.”

Ní ti fífi ohun gbogbo sábẹ́ rẹ̀, ṣùgbọ́n àwa kò ì tí ì rí ohun kan tí ó kù tí kò sí ní abẹ́ àkóso rẹ̀. Síbẹ̀ nísinsin yìí àwa kò ì tí ì rí pé ó fi ohun gbogbo sábẹ́ ìṣàkóso rẹ̀ 9Ṣùgbọ́n àwa rí Jesu ẹni tí a rẹ̀ sílẹ̀ díẹ̀ ju àwọn angẹli lọ fún àkókò díẹ̀, àní Jesu, ẹni tí a fi ògo àti ọlá dé ní adé nítorí ìjìyà wa; kí ó lè tọ́ ikú wò fún olúkúlùkù ènìyàn nípa oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run.

10Nítorí pé ó yẹ fún Ọlọ́run, nítorí nípasẹ̀ ẹni tí ohun gbogbo ṣẹ̀ wà, láti mú àwọn ọmọ púpọ̀ wá sínú ògo, láti ṣe balógun ìgbàlà wọn ni àṣepé nípa ìjìyà. 11Nítorí àti ẹni tí ń sọ ni di mímọ́ àti àwọn tí a ń sọ di mímọ́, láti ọ̀dọ̀ ẹnìkan ṣoṣo ni gbogbo wọn ti wá: Nítorí èyí ni kò ṣe tijú láti pè wọ́n ni arákùnrin. 122.12: Sm 22.22.Àti wí pé,

“Èmi ó sọ̀rọ̀ orúkọ rẹ̀ fún àwọn ará mi,

ni àárín ìjọ ni èmi yóò kọrin ìyìn rẹ̀.”

132.13: Isa 8.17-18.Àti pẹ̀lú,

“Èmi yóò gbẹ́kẹ̀ mi lé e.”

Àti pẹ̀lú,

“Kíyèsi í, èmi rèé, èmi àti àwọn ọmọ tí Ọlọ́run fi fún mi.”

14Ǹjẹ́ ni ìwọ̀n bí àwọn ọmọ tí ṣe alábápín ará àti ẹ̀jẹ̀, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni òun pẹ̀lú sì ṣe alábápín nínú ohun kan náà; kí ó lè ti ipa ikú rẹ̀ pa ẹni tí ó ní agbára ikú run, èyí ni èṣù. 15Kí o sì lè gba gbogbo àwọn tí ó tìtorí ìbẹ̀rù ikú wà lábẹ́ ìdè lọ́jọ́ ayé wọn gbogbo kúrò lọ́wọ́ ìbẹ̀rù. 162.16: Isa 41.8-9.Nítorí pé, nítòótọ́, kì í ṣe àwọn angẹli ni ó ṣe ìrànlọ́wọ́ fún, ṣùgbọ́n àwọn irú-ọmọ Abrahamu ni ó ṣe ìrànlọ́wọ́ fún. 17Nítorí náà, ó yẹ pé nínú ohun gbogbo kí ó dàbí àwọn ará rẹ̀, kí ó lè jẹ́ aláàánú àti olóòtítọ́ alábojútó Àlùfáà nínú ohun tí i ṣe ti Ọlọ́run, kí o lè ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn. 18Nítorí níwọ̀n bí òun tìkára rẹ̀ ti jìyà tí a sì ti dán an wò, òun ní agbára láti ran àwọn tí a ń dánwò lọ́wọ́.

Holy Bible in Gĩkũyũ

Ahibirania 2:1-18

Gwathwo Gũthikĩrĩria

1Nĩ ũndũ ũcio-rĩ, nĩtwagĩrĩirwo kũrũmbũiya mũno ũhoro ũrĩa twanaigua, nĩguo tũtikae gũtũgũgio tweherio kuuma harĩ guo. 22:2 Gũcook 33:12; Atũm 7:53Tondũ-rĩ, angĩkorwo ũhoro ũrĩa waririo nĩ araika warĩ mũrũmu-rĩ, na mũndũ o wothe wareganaga na ũhoro ũcio na akaũremera nĩaherithagio o ũrĩa kwagĩrĩire-rĩ, 32:3 Luk 1:2; Ahib 10:29tũngĩkĩaga atĩa kũherithio tũngĩnyarara ũhonokio mũnene ũũ? Ũhonokio ũyũ, ũrĩa waambire kũhunjio nĩ Mwathani, nĩwacookire gwĩkĩrwo hinya kũrĩ ithuĩ nĩ andũ arĩa maamũiguire. 42:4 1Akor 12:4; Aef 2:9Ningĩ Ngai agĩĩkĩra ũhoro ũyũ ũira atĩ nĩ wa ma na ũndũ wa kuonania marũũri na morirũ, o na kũringa ciama cia mĩthemba mĩingĩ, na akĩheana iheo cia Roho Mũtheru kũrĩ andũ kũringana na wendi wake.

Jesũ gũtuuo ta Ariũ a Nyina

5Thĩ ĩrĩa tũkwaria ũhoro wayo, araika tio maaheetwo wathani wayo. 62:6-8 Thab 8:4-6No nĩ harĩ mũndũ mũna ũheanĩte ũira handũ hamwe akoiga atĩrĩ:

“Mũndũ akĩrĩ kĩ tondũ ũikaraga ũkĩmwĩciiragia,

nake mũrũ wa mũndũ akĩrĩ kĩ atĩ nĩkĩo ũmũmenyagĩrĩra?

7Watũmire atigie o hanini aiganane na araika,

na ũkĩmũhumba thũmbĩ ya riiri o na gĩtĩĩo,

8na ũkĩiga indo ciothe rungu rwa magũrũ make aciathage.”

Nake akĩiga indo ciothe rungu rwa mũndũ-rĩ, hatirĩ kĩndũ o na kĩrĩkũ Ngai aatigire gĩtarĩ watho-inĩ wa mũndũ. No rĩu tũtionaga indo ciothe irĩ watho-inĩ wa mũndũ. 92:9 Atũm 3:13No tuonaga Jesũ, ũrĩa gwa kahinda kanini watuĩtwo mũnini gũkĩra araika, no rĩu ekĩrĩtwo thũmbĩ ya riiri na ya gĩtĩĩo nĩ tondũ nĩanyariirĩkire na agĩkua, nĩgeetha, nĩ ũndũ wa Wega wa Ngai atuĩke wa gũcama gĩkuũ handũ ha andũ othe.

102:10 Arom 11:36; Luk 24:26Nĩgũkorwo nĩ kwagĩrĩire atĩ Ngai, ũrĩa wombire indo ciothe na itũũraga nĩ ũndũ wake-rĩ, atũme mwambĩrĩria wa ũhonokio wao aagĩrĩre kũna kũna na ũndũ wa kũnyamario nĩguo arehe ciana nyingĩ riiri-inĩ wake. 112:11 Ahib 13:12; Math 28:10Jesũ ũrĩa ũtũmaga andũ matuĩke atheru, o hamwe na acio matuĩtwo atheru, othe matuĩkaga andũ a nyũmba ĩmwe. Nĩ ũndũ ũcio Jesũ ndaconokaga akĩmeeta ariũ na aarĩ a Ithe. 122:12 Thab 22:22Akoiga atĩrĩ,

“Nĩngoimbũra rĩĩtwa rĩaku kũrĩ ariũ na aarĩ a Baba;

nĩngainaga nyĩmbo cia gũkũgooca ndĩ kĩũngano-inĩ.”

132:13 Isa 8:17-18Ningĩ akoiga atĩrĩ,

“Niĩ ngũiga mwĩhoko wakwa harĩ Ngai.”

O na ningĩ akoiga atĩrĩ,

“Niĩ ũyũ haha, na ciana iria Ngai aaheete.”

142:14 Joh 1:14; Kĩam 3:15; 1Joh 3:8Kuona atĩ ciana icio irĩ na mwĩrĩ na thakame-rĩ, we o nake aatuĩkire o tao mwĩrĩ-inĩ, nĩgeetha na ũndũ wa gĩkuũ gĩake ahote kwananga ũrĩa ũrĩ na hinya wa gĩkuũ, nake nĩwe mũcukani, 15na ohore arĩa matũire mohetwo ũkombo-inĩ matukũ mao mothe nĩ ũndũ wa gwĩtigĩra gĩkuũ. 162:16 Luk 3:8Nĩgũkorwo ti-itherũ ti araika ateithagia, no ateithagia rũciaro rwa Iburahĩmu. 172:17 Ahib 4:14, 15; Arom 3:25Na nĩ ũndũ ũcio no nginya angĩahaananirio na ariũ na aarĩ a Ithe maũndũ-inĩ mothe, nĩguo atuĩke mũthĩnjĩri-Ngai ũrĩa mũnene ũiyũrĩtwo nĩ tha na mwĩhokeku agĩtungatĩra Ngai, na nĩguo arute horohio nĩ ũndũ wa mehia ma kĩrĩndĩ. 18Nĩgũkorwo we mwene nĩathĩĩnĩkire rĩrĩa aageragio-rĩ, nĩahotaga gũteithia andũ arĩa mageragio.