Hagai 2 – YCB & GKY

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Hagai 2:1-23

Ẹwà Tẹmpili tuntun náà

1Ní ọjọ́ kọkànlélógún oṣù keje, ni ọ̀rọ̀ Olúwa wá nípasẹ̀ wòlíì Hagai wí pé: 2“Sọ fún Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli, baálẹ̀ Juda, àti Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà àti àwọn ènìyàn yòókù. Béèrè lọ́wọ́ wọn pé, 3‘Ta ni nínú yín tí ó kù tí ó sì ti rí ilé yìí ní ògo rẹ̀ àkọ́kọ́? Báwo ni ó ṣe ri sí yín nísinsin yìí? Ǹjẹ́ kò dàbí asán lójú yín? 4Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, múra gírí, ìwọ Serubbabeli,’ ni Olúwa wí. ‘Múra gírí, ìwọ Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà. Ẹ sì múra gírí gbogbo ẹ̀yin ènìyàn ilẹ̀ náà;’ ni Olúwa wí, ‘kí ẹ sì ṣiṣẹ́. Nítorí èmi wà pẹ̀lú yín;’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. 5‘Èyí ni ohun tí Èmi fi bá a yín dá májẹ̀mú nígbà tí ẹ jáde kúrò ní Ejibiti, bẹ́ẹ̀ ni Ẹ̀mí ì mi sì wà pẹ̀lú yín. Ẹ má ṣe bẹ̀rù.’

6“Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé: ‘Láìpẹ́ jọjọ, Èmi yóò mi àwọn ọrun àti ayé, Òkun àti ìyàngbẹ ilẹ̀ lẹ́ẹ̀kan sí i. 7Èmi yóò mi gbogbo orílẹ̀-èdè, ìfẹ́ gbogbo orílẹ̀-èdè yóò fà sí tẹmpili yìí, Èmi yóò sì kún ilé yìí pẹ̀lú ògo;’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. 8‘Tèmi ni fàdákà àti wúrà,’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. 9‘Ògo ìkẹyìn ilé yìí yóò pọ̀ ju ti ìṣáájú lọ;’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: ‘Àti ní ìhín yìí ni Èmi ó sì fi àlàáfíà fún ni,’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.”

Ìbùkún fún àwọn ènìyàn tí a sọ di àìmọ́

10Ní ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹsànán ní ọdún kejì Dariusi, ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ wòlíì Hagai wá pé: 11“Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: ‘Béèrè lọ́wọ́ àwọn àlùfáà ohun tí òfin wí pé: 12Bí ẹnìkan bá gbé ẹran mímọ́ ní ìṣẹ́tí aṣọ rẹ̀, tí ìṣẹ́tí aṣọ rẹ̀ kan àkàrà tàbí ọbẹ̀, wáìnì, òróró tàbí oúnjẹ mìíràn, ǹjẹ́ yóò ha jẹ́ mímọ́ bí?’ ”

Àwọn àlùfáà sì dáhùn wí pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́.”

13Nígbà náà ni Hagai wí pé, “Bí ẹnìkan tí ó jẹ́ aláìmọ́ nípa fífi ara kan òkú bá fi ara kan ọ̀kan lára nǹkan wọ̀nyí, ǹjẹ́ yóò ha jẹ́ aláìmọ́?”

Àwọn àlùfáà sì dáhùn wí pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, yóò jẹ́ aláìmọ́.”

14Nígbà náà ni Hagai dáhùn ó sì wí pé, “ ‘Bẹ́ẹ̀ ni ènìyàn wọ̀nyí rí, bẹ́ẹ̀ sì ni orílẹ̀-èdè yìí rí níwájú mi,’ ni Olúwa wí. ‘Bẹ́ẹ̀ sì ni olúkúlùkù iṣẹ́ ọwọ́ wọn; èyí tí wọ́n sì fi rú ẹbọ níbẹ̀ jẹ́ aláìmọ́.

15“ ‘Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ẹ ro èyí dáradára láti òní yìí lọ, ẹ kíyèsi bí nǹkan ṣe rí tẹ́lẹ̀, a to òkúta kan lé orí èkejì ní tẹmpili Olúwa. 16Nígbà tí ẹnikẹ́ni bá dé ibi òkìtì òṣùwọ̀n ogun, mẹ́wàá péré ni yóò ba níbẹ̀. Nígbà tí ẹnikẹ́ni bá dé ibi ìfúntí wáìnì láti wọn àádọ́ta ìwọ̀n, ogún péré ni yóò ba níbẹ̀. 17Mo fi ìrẹ̀dànù, ìmúwòdù àti yìnyín bá gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ yín jẹ; síbẹ̀ ẹ̀yin kò yípadà sí ọ̀dọ̀ mi,’ ni Olúwa wí. 18‘Láti òní lọ, láti ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹsànán yìí kí ẹ kíyèsi, kí ẹ sì rò ó dáradára, ọjọ́ ti a fi ìpìlẹ̀ tẹmpili Olúwa lélẹ̀, rò ó dáradára: 19Ǹjẹ́ èso ha wà nínú abà bí? Títí di àkókò yìí, àjàrà àti igi ọ̀pọ̀tọ́ àti pomegiranate, àti igi olifi kò ì tí ì so èso kankan.

“ ‘Láti òní lọ ni èmi yóò bùkún fún un yin.’ ”

Serubbabeli òrùka èdìdì Olúwa

20Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tún tọ Hagai wá nígbà kejì, ní ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù náà pé: 21“Sọ fún Serubbabeli baálẹ̀ Juda pé èmi yóò mi àwọn ọ̀run àti ayé. 22Èmi yóò bi ìtẹ́ àwọn ìjọba ṣubú, Èmi yóò sì pa agbára àwọn aláìkọlà run; Èmi yóò sì dojú àwọn kẹ̀kẹ́ ogun dé, àti àwọn tí ń gùn wọ́n; ẹṣin àti àwọn ẹlẹ́ṣin yóò ṣubú; olúkúlùkù nípa idà arákùnrin rẹ̀.”

23Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Ní ọjọ́ náà, ìwọ ìránṣẹ́ mi Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli, Èmi yóò mú ọ, Èmi yóò sì sọ ọ di bí òrùka èdìdì mi, nítorí mo ti yan ọ, ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.”

Holy Bible in Gĩkũyũ

Hagai 2:1-23

Riiri wa Nyũmba ĩyo Njerũ

12:1 Alaw 23:34Na rĩrĩ, mũthenya wa mĩrongo ĩĩrĩ na ũmwe, mweri wa mũgwanja, ndũmĩrĩri ya Jehova nĩyakinyĩire mũnabii Hagai, akĩĩrwo atĩrĩ, 22:2 1Maũ 6:15“Arĩria Zerubabeli mũrũ wa Shealitieli, mwathi wa bũrũri wa Juda, na Joshua mũrũ wa Jehozadaki, mũthĩnjĩri-Ngai ũrĩa mũnene, na andũ othe arĩa matigaire, ũmoorie atĩrĩ, 32:3 Ezar 3:12; Zek 4:10‘Nũũ wanyu ũtigarĩte wonire nyũmba ĩno na riiri wayo wa mbere? Mũrona ĩhaana atĩa rĩu? Githĩ mũtiramĩona ĩhaana ta kĩndũ gĩa tũhũ?’ 42:4 Zek 8:9; Atũm 7:9Jehova ekuuga atĩrĩ, ‘Gĩa na hinya, wee Zerubabeli, na ũgĩe na hinya, wee Joshua mũrũ wa Jehozadaki, mũthĩnjĩri-Ngai ũrĩa mũnene, gĩai na hinya inyuĩ andũ othe a bũrũri, na mũrute wĩra, nĩgũkorwo ndĩ hamwe na inyuĩ.’ Ũguo nĩguo Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga. 52:5 Kĩam 6:18; Neh 9:20‘Ũguo nĩguo ndaarĩkanĩire na inyuĩ, rĩrĩa mwoimire bũrũri wa Misiri, na Roho wakwa egũtũũra thĩinĩ wanyu. Tigai gwĩtigĩra.’

62:6 Thaam 19:18; Ahib 12:26“Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga atĩrĩ; ‘Thuutha wa kahinda kanini nĩngathingithia igũrũ na thĩ rĩngĩ, na thingithie iria na thĩ nyũmũ. 72:7 Isa 60:7; Luk 2:32Nĩngathingithia ndũrĩrĩ ciothe, nake ũrĩa wĩriragĩrio nĩ ndũrĩrĩ ciothe nĩagooka, na niĩ nĩngaiyũria nyũmba ĩno riiri,’ ũguo nĩguo Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga. 8Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga atĩrĩ, ‘Betha nĩ yakwa, o na thahabu nĩ yakwa. 92:9 Thab 85:9; Alaw 26:6Riiri wa nyũmba ĩno ũgaakorwo ũrĩ mũnene gũkĩra riiri wa nyũmba ĩrĩa ya mbere,’ ũguo nĩguo Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga. ‘Na handũ haha nĩngaheana thayũ,’ ũguo nĩguo Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga.”

Irathimo cia Andũ arĩa Marĩ na Thaahu

10Mũthenya wa mĩrongo ĩĩrĩ na ĩna, mweri wa kenda, mwaka wa keerĩ wa gũthamaka kwa Dario, ndũmĩrĩri ya Jehova nĩyakinyĩire mũnabii Hagai akĩĩrwo atĩrĩ, 112:11 Alaw 10:10; Jer 18:18“Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga atĩrĩ, ‘Ũriai athĩnjĩri-Ngai ũrĩa watho ugĩte: 122:12 Jer 11:15; Math 23:19Mũndũ angĩkuua nyama nyamũre ruuno-inĩ rwa nguo yake, naruo ruuno rũhutie mũgate, kana thubu, kana ndibei, kana maguta, o na kana irio ingĩ-rĩ, irio icio ciatuĩka nyamũre?’ ”

Nao athĩnjĩri-Ngai magĩcookia atĩrĩ, “Aca.”

132:13 Ndar 19:13Ningĩ Hagai akĩmooria atĩrĩ, “Mũndũ ũrĩ na thaahu nĩ ũndũ wa kũhutania na kĩimba, angĩhutia kĩndũ kĩmwe gĩa icio-rĩ, kĩndũ kĩu no kĩnyiitwo nĩ thaahu?”

Nao athĩnjĩri-Ngai magĩcookia atĩrĩ, “Ĩĩ, no kĩnyiitwo nĩ thaahu.”

142:14 Thab 51:17; Isa 1:13Ningĩ Hagai akĩmeera atĩrĩ, “Jehova ekuuga atĩrĩ, ‘Ũguo noguo andũ aya na rũrĩrĩ rũrũ matariĩ maitho-inĩ makwa; ũrĩa wothe meekaga na kĩrĩa gĩothe marutaga kũu, kĩrĩ na thaahu.

152:15 Ezar 4:24“ ‘Na rĩrĩ, mwĩcũraniei wega ũhoro ũyũ kuuma ũmũthĩ, mũtaranie ũrĩa maũndũ maatariĩ mbere ya rĩrĩa gũtaarĩ ihiga rĩaigĩrĩirwo igũrũ wa rĩngĩ mwako-inĩ wa hekarũ ĩno ya Jehova. 162:16 Ayub 24:11; Hag 1:6Mũndũ o wothe angĩathiire hĩba-inĩ ya ngano ya ithimi mĩrongo ĩĩrĩ, aakoraga no ithimi ikũmi. Mũndũ o wothe angĩathiire itangi-inĩ rĩa ndibei erĩgĩrĩire gũtahia ithimi mĩrongo ĩtano, aakoraga o mĩrongo ĩĩrĩ. 172:17 Gũcook 28:22; Amos 4:6Ndathũkirie wĩra wothe wa moko manyu na mbaa, na mbuu na mbura ya mbembe,2:17 Rũhuho rũhiũ na mbura ya mbembe ciatũmagĩrwo nĩ Ngai kũhũũra andũ nĩ ũndũ wa ũremi wao. no inyuĩ mũtiigana kũnjookerera,’ ũguo nĩguo Jehova ekuuga. 18Kuuma ũmũthĩ na gũthiĩ na mbere, kuuma mũthenya ũyũ wa mweri mĩrongo ĩĩrĩ na inya, mweri wa kenda, mwĩcũraniei wega ũhoro wa mũthenya ũrĩa mũthingi wa hekarũ ya Jehova wakirwo. Ta mwĩcũraniei wega: 192:19 Thaam 28:33; Kĩam 12:2Nĩ hakĩrĩ o na mbeũ ĩtigarĩte ikũmbĩ-inĩ? Nginyagia rĩu, mĩthabibũ, na mĩkũyũ, na mĩkomamanga, o na mĩtamaiyũ ndĩrĩ ĩragĩa na maciaro.

“ ‘Kuuma ũmũthĩ nĩndĩrĩmũrathimaga.’ ”

Zerubabeli, Gĩcũhĩ kĩa Jehova

202:20 Ezar 5:1; Hag 1:15Ningĩ ndũmĩrĩri ya Jehova nĩyakinyĩire Hagai hĩndĩ ya keerĩ, mweri mĩrongo ĩĩrĩ na inya wa mweri ũcio, akĩĩrwo atĩrĩ, 21“Arĩria Zerubabeli mwathi wa Juda, ũmwĩre atĩ nĩngathingithia igũrũ na thĩ. 222:22 Dan 2:44; Mik 5:10Nĩngangʼaũrania itĩ cia ũnene, na hehenje hinya wa mothamaki ma thĩ ngʼeni. Nĩngakurumania ngaari cia ita, na atwarithia a cio; na ndungumanie mbarathi hamwe na ahaici a cio, o mũndũ arũndwo na rũhiũ rwa njora rwa mũrũ wa nyina.

232:23 Isa 2:11; Math 1:12“Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga atĩrĩ, ‘Mũthenya ũcio-rĩ, nĩngakwamũkĩra, wee ndungata yakwa Zerubabeli mũrũ wa Shealitieli,’ ũguo nĩguo Jehova ekuuga. ‘Ningĩ nĩngagũtua ta gĩcũhĩ gĩakwa gĩa kĩara, gĩkurure rũũri rwakwa, nĩgũkorwo nĩngũthuurĩte,’ ũguo nĩguo Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga.”