Habakuku 2 – YCB & GKY

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Habakuku 2:1-20

Ìdáhùn Ọlọ́run sí ìráhùn wòlíì Habakuku

12.1: Isa 21.8.Èmi yóò dúró lórí ibusọ́ mi láti máa wòye

Èmi yóò sì gbé ara mi ka orí alóre

Èmi yóò si ṣọ́ láti gbọ́ ohun tí yóò sọ fún mi

àti èsì ti èmi yóò fún ẹ̀sùn yìí nígbà tó bá ń bá mi wí.

Ìdáhùn Olúwa

2Nígbà náà ni Olúwa dáhùn pé:

“Kọ ìṣípayá náà sílẹ̀

kí o sì fi hàn ketekete lórí wàláà

kí ẹni tí ń kà á, lè máa sáré.

32.3: Hb 10.37.Nítorí ìṣípayá náà jẹ́ tí ìgbà kan tí a múra sílẹ̀ dè;

yóò máa yára sí ìgbẹ̀yìn

kí yóò sìsọ èké.

Bí o tilẹ̀ lọ́ra, dúró dè é;

nítorí, dájúdájú, yóò dé, kí yóò sí pẹ́.”

42.4: Ro 1.17; Ga 3.11; Hb 10.38-39.“Kíyèsi, ọkàn rẹ tí ó gbéga;

Ìfẹ́ rẹ̀ kò dúró ṣinṣin nínú rẹ̀,

ṣùgbọ́n olódodo yóò wa nípa ìgbàgbọ́ rẹ̀.

5Bẹ́ẹ̀ ni pẹ̀lú, nítorí tí ọtí wáìnì ni ẹ̀tàn,

agbéraga ènìyàn òun, kò sì ní sinmi

ẹni tí ó sọ ìwọra rẹ di gbígbòòrò bí isà òkú,

ó sì dàbí ikú, a kò sì le tẹ́ ẹ lọ́rùn,

ó kó gbogbo orílẹ̀-èdè jọ sí ọ̀dọ̀

ó sì gba gbogbo ènìyàn jọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀.

6“Gbogbo àwọn wọ̀nyí kì yóò máa pa òwe sí i tí wọn yóò sì máa kọ orin òwe sí i wí pé,

“ ‘Ègbé ni fún ẹni tí ń mu ohun tí kì í ṣe tirẹ̀ pọ̀ sí i!

Tí ó sì sọ ara rẹ̀ di ọlọ́rọ̀ nípasẹ̀ ìlọ́nilọ́wọ́gbà!

Eléyìí yóò ha ti pẹ́ tó?’

7Ǹjẹ́ ẹni ti ó yọ ọ́ lẹ́nu, kí yóò ha dìde ní òjijì?

Àti àwọn tí ó wàhálà rẹ kì yóò jí, kí wọn ó sì dẹ́rùbà ọ́?

Nígbà náà ni ìwọ yóò wa dí ìkógun fún wọn.

8Nítorí ìwọ ti kó orílẹ̀-èdè púpọ̀,

àwọn ènìyàn tókù yóò sì kó ọ

nítorí ìwọ tí ta ẹ̀jẹ̀ ènìyàn sílẹ̀; nítorí ẹ̀jẹ̀

Ìwọ tí pa ilẹ̀ àti ìlú ńlá run

àti gbogbo ènìyàn to ń gbé inú rẹ̀.

9“Ègbé ni fún ẹni tí ń jẹ èrè ìjẹkújẹ sí ilé rẹ̀,

tí o sí gbé ìtẹ́ rẹ̀ lórí ibi gíga,

kí a ba le gbà á sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ ibi!

10Ìwọ ti gbìmọ̀ ìtìjú sí ilé rẹ

nípa kíké ènìyàn púpọ̀ kúrò;

ìwọ sì ti pàdánù ẹ̀mí rẹ

11Nítorí tí òkúta yóò kígbe jáde láti inú ògiri wá,

àti ìtí igi láti inú igi rírẹ́ wá yóò sì dá a lóhùn.

12“Ègbé ni fún ẹni tí ó fi ẹ̀jẹ̀ kọ́ ìlú,

tí o sì fi àìṣedéédéé tẹ ìlú ńlá dó?

13Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun kò ha ti ṣètò rẹ̀ pé

làálàá àwọn ènìyàn jẹ́ epo fún iná

kí àwọn orílẹ̀-èdè náà sì máa ṣe wàhálà fún asán?

14Nítorí tí ayé yóò kún fún ìmọ̀ ògo Olúwa,

bí omi ti bo Òkun.

15“Ègbé ni fún ẹni tí ó fi ohun mímu fún aládùúgbò rẹ̀,

tí ó sì fi ọtí-lílé rẹ̀ fún un, tí o sì jẹ́ kó mu àmupara,

kí ìwọ kí ó ba lè wo ìhòhò wọn”

16Ìtìjú yóò bò ọ́ dípò ògo, ìwọ náà mu pẹ̀lú

kí ìhòhò rẹ kí ó lè hàn,

ago ọwọ́ ọ̀tún Olúwa, yóò yípadà sí ọ,

ìtìjú yóò sì bo ògo rẹ.

17Nítorí ìwà ipá tí ó tí hù sí Lebanoni yóò bò ọ́,

àti ìparun àwọn ẹranko yóò dẹ́rùbà ọ́ mọ́lẹ̀

Nítorí ìwọ tí ta ẹ̀jẹ̀ ènìyàn sílẹ̀;

ìwọ tí pa ilẹ̀ náà àti ìlú ńlá run àti gbogbo àwọn tí ń gbé inú rẹ̀.

18“Èrè kí ni òrìṣà ni, tí oníṣọ̀nà rẹ̀ fi gbẹ́ ẹ,

ère dídá ti ń kọ ni èké?

Nítorí ti ẹni ti ó dá a gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ lé ohun tí ó fúnrarẹ̀ dá;

ó sì mọ ère tí kò le fọhùn.

19Ègbé ni fún ẹni ti ń sọ fún igi pé, ‘di alààyè?’

Fún òkúta tí kò lè fọhùn pé, ‘Dìde’

Ǹjẹ́ òun lè tọ́ ni sí ọ̀nà?

Wúrà àti fàdákà ni a fi bò ó yíká;

kò sì sí èémí kan nínú rẹ.”

202.20: Sf 1.7; Sk 2.13.Ṣùgbọ́n Olúwa wà nínú tẹmpili mímọ́ rẹ̀;

Ẹ jẹ́ kí gbogbo ayé parọ́rọ́ níwájú rẹ.

Holy Bible in Gĩkũyũ

Habakuku 2:1-20

12:1 Thab 48:13; Ezek 3:17Nĩngũrũgama handũ hakwa ha kũrangĩra,

na njikare o hau rũthingo igũrũ.

Njetereire njigue ũrĩa ekũnjĩĩra,

nĩguo menye ũrĩa ingĩcookia nĩ ũndũ wa iteta rĩĩrĩ.

Icookia rĩa Jehova

22:2 Jer 36:2; Kũg 1:19Nake Jehova akĩnjookeria atĩrĩ,

“Andĩka ũguũrio ũyũ,

ũwandĩke wega ihengere-inĩ na ndemwa nene,

nĩgeetha ũthomeke wega,

o na mũndũ angĩkorwo atengʼerete.

32:3 Ezek 12:25; Dan 8:17Nĩgũkorwo ũguũrio ũyũ wetereire ihinda rĩrĩa rĩtuĩtwo;

waragia ũhoro wa matukũ ma mũthia,

na ndũngĩtuĩka wa maheeni.

O na ũngĩikara mũno-rĩ, weterere.

Ti-itherũ nĩũkahingio, na ndũgatĩĩrio.

42:4 Arom 1:17; Agal 3:11“Atĩrĩrĩ, mũndũ mwĩtĩĩi-rĩ,

merirĩria maake ti marũngĩrĩru;

no mũndũ ũrĩa mũthingu

agatũũra muoyo nĩ ũndũ wa gwĩtĩkia gwake;

52:5 Thim 20:1; Hab 1:9ti-itherũ, mũndũ ũcio mwĩtĩĩi nĩakunyanagĩrwo nĩ ndibei;

nĩ mwĩtĩĩi na ndarĩ hĩndĩ ahurũkaga.

Tondũ akorokete ta mbĩrĩra,

na o ta ũrĩa gĩkuũ gĩtaiganagia,

o nake ndaiganagia;

acookanagĩrĩria ndũrĩrĩ ciothe harĩ we,

na agataha andũ a ndũrĩrĩ ciothe.

6“Githĩ andũ othe matikamũthekerera makĩmũnyũrũragia, na mamũnyarare, makiugaga atĩrĩ,

“ ‘Kaĩ mũndũ ũrĩa wĩigagĩra indo cia ũici,

na agetongia na indo cia ũtunyani arĩ na haaro-ĩ!

Egũtũũra ekaga ũguo nginya-rĩ?’

72:7 Thim 29:1Andũ arĩa ũrĩ na thiirĩ wao githĩ matigagũũkĩrĩra o rĩmwe?

Githĩ matikaarahũka, na matũme ũinaine,

macooke makũnyamarie?

82:8 Isa 33:1; Obad 1:15; Ezek 39:10Tondũ nĩũtahĩte ndũrĩrĩ nyingĩ indo ciao,

matigari ma ndũrĩrĩ icio, nĩmagagũtaha indo o nawe.

Nĩ ũndũ nĩũitĩte thakame ya andũ,

na ũkaananga mabũrũri, na matũũra manene, o na arĩa othe marĩ kuo.

92:9 Jer 22:13; Ayub 39:27“Mũndũ ũrĩa wakaga wathani wake,

na agetongia na uumithio ũtarĩ wa kĩhooto,

nĩgeetha aake nyũmba yake handũ igũrũ

nĩguo ehonokie ndakanyiitwo nĩ mwanangĩko,

kaĩ arĩ na haaro-ĩ!

102:10 Jer 26:19Wee wanaciirĩra kũniinwo kwa ndũrĩrĩ nyingĩ,

ũgaconorithia nyũmba yaku mwene,

na ũkoorwo nĩ muoyo waku.

112:11 Josh 24:27; Luk 19:40Mahiga ma rũthingo nĩmakanĩrĩra,

na mĩgamba ya mbaũ nĩĩkamũkĩria.

122:12 Mik 3:10; Ezek 22:2“Mũndũ ũrĩa wakithagia itũũra inene na ũiti wa thakame,

na akahaanda itũũra na njĩra cia ũmaramari, kaĩ arĩ na haaro-ĩ!

13Githĩ Jehova Mwene-Hinya-Wothe ndatuĩte

atĩ wĩra wa andũ no ngũ cia gwakĩrĩria mwaki,

na atĩ ndũrĩrĩ ciĩnogagia o tũhũ?

142:14 Isa 11:9Nĩgũkorwo thĩ nĩĩkaiyũrwo nĩ ũmenyo wa riiri wa Jehova,

o ta ũrĩa maaĩ maiyũrĩte iria-inĩ.

15“Mũndũ ũrĩa ũheaga andũ a itũũra rĩake njoohi,

akamatahĩria mondo-inĩ ya rũũa ya ndibei nginya makarĩĩo,

nĩgeetha erorere njaga yao, kaĩ arĩ na haaro-ĩ!

162:16 Maca 4:21; Thab 16:5Ũkaiyũrwo nĩ thoni, handũ ha kũgĩa na riiri.

Rĩĩrĩ nĩrĩo ihinda rĩaku!

Nyua, ũrĩĩo,

nayo njaga yaku yoneke!

Gĩkombe kuuma guoko-inĩ kwa ũrĩo kwa Jehova

nĩkĩragũkora, na njono nĩikũhumbĩra riiri waku.

172:17 Jer 51:35Haaro ĩrĩa ũrutĩire Lebanoni-rĩ, nĩĩgakũhubĩkania,

na wanangi waku wa nyamũ-rĩ, nĩũgakũmakia mũno.

Nĩ ũndũ nĩũitĩte thakame ya andũ,

na ũkaananga mabũrũri, na matũũra manene, na arĩa othe marĩ kuo.

182:18 1Sam 12:21; Alaw 26:1“Mũhianano mũicũhie nĩ wa bata ũrĩkũ mũndũ aarĩkia kũwacũhia?

O naguo mũhianano wa gũtwekio ũrĩa ũtũmaga andũ maheeneke nĩ wa bata ũrĩkũ?

Nĩgũkorwo ũrĩa ũũthondekaga ehokaga kĩrĩa ombĩte;

athondekaga mĩhianano ĩtaaragia.

192:19 1Akor 12:2; 1Ath 18:27; Hos 4:12Mũndũ ũrĩa wĩraga rũbaũ atĩrĩ, ‘Gĩa na muoyo!’

Kana akeera ihiga rĩtarĩ muoyo atĩrĩ, ‘Arahũka!’ Kaĩ arĩ na haaro-ĩ!

Indo ta icio ciakĩhota kuonia mũndũ njĩra?

Ihumbĩtwo thahabu na betha;

no itirĩ na mĩhũmũ thĩinĩ wacio.

20No rĩrĩ, Jehova arĩ hekarũ-inĩ yake theru;

thĩ yothe nĩĩkire ki ĩrĩ mbere yake.”