2 Tẹsalonika 2 – YCB & PCB

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

2 Tẹsalonika 2:1-17

Ọkùnrin aláìlófin náà

12.1: 1Tẹ 4.15-17.Ní ti bíbọ̀ Jesu Kristi Olúwa wa, àti ti ìpéjọ wa sọ́dọ̀ rẹ̀, àwa wí fún yín ará, 22.2: 2Tẹ 3.17.kí ọkàn yín má ṣe àìbalẹ̀, tàbí kí ẹ má ṣe jáyà nípa àsọtẹ́lẹ̀, ìròyìn tàbí lẹ́tà tí ó lè fi ara jọ èyí tí ó le wá láti ọ̀dọ̀ wa, tí yóò máa wí pé ọjọ́ Olúwa ti dé ná. 32.3: Ef 5.6-8; Da 7.8,25; 11.36; If 13.5; Jh 17.12.Ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni kí ó tàn yín jẹ ní ọ̀nàkọnà, nítorí pé ọjọ́ náà kì yóò dé, bí kò ṣe pé ìṣọ̀tẹ̀ bá kọ́ ṣẹlẹ̀, tí a sì fi ẹni ẹ̀ṣẹ̀ hàn, tí í ṣe ọmọ ègbé. 42.4: El 28.2.Òun yóò lòdì sí, yóò sì gbé ara rẹ̀ ga sí gbogbo ohun tí a ń pè ní Ọlọ́run tàbí tí a ń sìn, dé ibi pé yóò gbé ara rẹ̀ jókòó nínú tẹmpili Ọlọ́run, tí yóò sì pe ara rẹ̀ ní Ọlọ́run.

52.5: 1Tẹ 3.4.Ṣé ẹ̀yin kò rántí pé nígbà tí mo wà pẹ̀lú yín, mo ń sọ àwọn nǹkan wọ̀nyí fún un yín. 6Àti pé nísinsin yìí, ẹ̀yin mọ ohun tí ń dá a dúró, kí a bá a lè fi í hàn ní àkókò rẹ̀ gan an. 7Nítorí agbára ìkọ̀kọ̀ ẹni ẹ̀ṣẹ̀ ti ń ṣiṣẹ́; ṣùgbọ́n ẹni tí ń dènà yóò máa ṣe bẹ́ẹ̀ títí a ó fi mú un kúrò ní ọ̀nà. 82.8: Isa 11.4.Nígbà náà ni a ó fi ẹni ẹ̀ṣẹ̀ hàn, ẹni tí Jesu Olúwa yóò fi èémí ẹnu rẹ̀ pa, tí yóò sì fi ọlá ìpadàbọ̀ rẹ̀ parun. 92.9: Mt 24.24; Jh 4.48.Wíwá ẹni ẹ̀ṣẹ̀ yóò rí bí iṣẹ́ Satani, gbogbo èyí tí a fihàn gẹ́gẹ́ bí àdàmọ̀dì iṣẹ́ ìyanu, àdàmọ̀dì ààmì àti àdàmọ̀dì idán, 10Ní gbogbo ọ̀nà búburú tí a fi ń tan àwọn tí ń ṣègbé jẹ. Wọ́n ṣègbé nítorí wọ́n kọ̀ láti fẹ́ràn òtítọ́ kí wọn sì di ẹni ìgbàlà. 112.11: Ro 1.28.Nítorí ìdí èyí, Ọlọ́run rán ohun tó ń ṣiṣẹ́ ìṣìnà sí wọn kí wọn lè gba èké gbọ́, 12kí wọn kí ó lè gba ìdálẹ́bi, àní àwọn tí kò gba òtítọ́ gbọ́, ṣùgbọ́n tí wọ́n ní inú dídùn nínú ìwà búburú.

Ẹ dúró ṣinṣin

132.13: 2Tẹ 1.3; Ef 1.4; 1Pt 1.2.Ṣùgbọ́n, ohun tí ó tọ́ fún wa ni láti máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run nígbà gbogbo nítorí yín, ará olùfẹ́ ní ti Olúwa, nítorí láti ìbẹ̀rẹ̀ ni Ọlọ́run ti yàn yín sí ìgbàlà nípa ìsọdimímọ́ ti Ẹ̀mí àti nípa gbígba òtítọ́ gbọ́. 14Òun ti pè yín sí èyí nípa ìhìnrere wa, kí ẹ̀yin kí ó lè pín nínú ògo Jesu Kristi Olúwa wa.

152.15: 1Kọ 16.13; 11.2.Nítorí náà ará, ẹ dúró ṣinṣin, kí ẹ sì di àwọn ẹ̀kọ́ wọ̀n-ọn-nì tí a kọ́ yín mú, yálà nípa ọ̀rọ̀ ẹnu tàbí lẹ́tà.

162.16: 1Tẹ 3.11; 1Pt 1.3.Ǹjẹ́ kí Jesu Kristi Olúwa wa tìkálára rẹ̀, àti Ọlọ́run baba wa, ẹni to ti fẹ́ wa, tí ó sì ti fi ìtùnú àìnípẹ̀kun àti ìrètí rere nípa oore-ọ̀fẹ́ fún wa. 17Kí ó mú ọkàn yín le, kí ó sì kún yín pẹ̀lú agbára nínú iṣẹ́ gbogbo àti ọ̀rọ̀ rere gbogbo.

Persian Contemporary Bible

دوم تسالونيکیان 2:1‏-17

ظهور مرد خبيث پيش از بازگشت مسيح

1‏-2اما سخنی نيز دربارهٔ بازگشت خداوند ما عيسی مسيح و جمع شدن ما به نزد او بگويم: گويا برخی می‌گويند كه روز بازگشت خداوند فرا رسيده است؛ برادران عزيز، خواهش می‌كنم از شنيدن اين گونه خبرهای نادرست، آرامش خود را از دست ندهيد. حتی اگر بگويند كه در اين زمينه رؤيايی ديده‌اند، يا پيغام خاصی از خدا گرفته‌اند، و يا از من نامه‌ای دريافت كرده‌اند، مطلقاً باور نكنيد. 3بگذاريد هر چه می‌خواهند، بگويند؛ ولی شما فريب سخنان ايشان را نخوريد.

اما بدانيد كه تا اين دو رويداد واقع نشود، آن روز نخواهد آمد: نخست، شورشی بر ضد خدا بر پا خواهد شد؛ دوم، آن مرد جهنمی كه عامل اين شورش است، ظهور خواهد كرد. 4او با هر چه كه مربوط به دين و خدا است، مخالفت خواهد نمود. حتی وارد خانهٔ خدا خواهد شد، و در آنجا نشسته، ادعا خواهد كرد كه خداست. 5آيا به ياد نداريد كه وقتی نزد شما بودم، اين را می‌گفتم؟ 6خودتان می‌دانيد چه كسی مانع آمدن اوست؛ زيرا او فقط زمانی می‌تواند ظهور كند كه وقتش رسيده باشد.

7و اما خرابكاريهايی كه آن شورشگر جهنمی به هنگام ظهورش انجام خواهد داد، از هم اكنون آغاز شده است؛ ولی خود او زمانی ظاهر خواهد شد كه آن كسی كه مانع اوست، از سر راه كنار برود. 8آنگاه آن مرد خبيث ظهور خواهد كرد. اما خداوند ما عيسی به هنگام بازگشت خود، او را با نَفَس دهان خويش هلاک كرده، با حضور خود نابود خواهد ساخت. 9اين مرد خبيث بوسيلهٔ قدرت شيطان ظهور خواهد كرد و آلت دست او خواهد بود؛ او با كارهای عجيب و حيرت‌انگيز خود همه را فريب داده، معجزات بزرگ انجام خواهد داد. 10كسانی كه فريب او را می‌خورند، آنانی هستند كه راه راست را رد كرده و راه جهنم را در پيش گرفته‌اند. ايشان حقيقت را دوست ندارند و آن را نمی‌پذيرند تا نجات يابند. 11از این رو، خدا اجازه خواهد داد تا با تمام وجود، اين دروغها را باور كنند. 12در نتيجه، تمام كسانی كه دروغ را پذيرفتند و راستی را رد نمودند و از گناه لذت برده، شاد شدند، به حق محكوم خواهند شد.

ايمانداران بايد پايدار بمانند

13اما ای برادران و ای محبوبان خدا، ما بايد هميشه برای وجود شما خدا را شكر كنيم، زيرا خدا از همان ابتدا شما را برگزيد تا نجات بخشد و بوسيلهٔ قدرت روح پاكش و ايمانتان به راستی، شما را پاک سازد. 14به همين منظور، او مژدهٔ نجات را بوسيلهٔ ما به شما رساند و از طريق ما، شما را دعوت كرد تا در جلال خداوند ما عيسی مسيح شريک گرديد.

15پس ای برادران عزيز، با توجه به اين مطالب، استوار باشيد و به حقايقی كه حضوراً و يا توسط نامه‌هايمان به شما آموختيم، محكم بچسبيد.

16خود خداوند ما عيسی مسيح و پدر ما خدا، كه ما را محبت نمود و از روی لطف بی‌پايان خويش، تسلی و اميد جاودانی به ما بخشيد، 17دلهای شما را تسلی عطا كند و شما را نيرو بخشد تا همواره كردار و گفتارتان نيک باشد.