2 Johanu 1 – YCB & CST

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

2 Johanu 1:1-13

11: 3Jh 1.Alàgbà,

Sì àyànfẹ́ obìnrin ọlọ́lá àti àwọn ọmọ rẹ̀, àwọn tí mo fẹ́ ní òtítọ́, kì í sì í ṣe èmi nìkan, ṣùgbọ́n gbogbo àwọn tí ó mọ òtítọ́ pẹ̀lú; 2nítorí òtítọ́ tí ń gbé inú wa, yóò sì bá wa gbé títí.

3Oore-ọ̀fẹ́, àánú, àti àlàáfíà, láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba, àti láti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi, Ọmọ Baba, yóò wà pẹ̀lú wa nínú òtítọ́ àti nínú ìfẹ́.

4Mo yọ̀ gidigidi pé mo rí nínú àwọn ọmọ rẹ tí ń rìn nínú òtítọ́, gẹ́gẹ́ bí Baba ti pa àṣẹ fún wa. 55: Jh 13.34.Ǹjẹ́ nísinsin yìí, mo bẹ̀ ọ́, obìnrin ọlọ́lá, kì í ṣe bí ẹni pé èmi ń kọ̀wé òfin tuntun kan sí ọ, bí kò ṣe èyí ti àwa tí ní ní àtètèkọ́ṣe, pé kí àwa fẹ́ràn ara wa. 66: 1Jh 5.3.Èyí sì ni ìfẹ́, pé, kí àwa máa rin nípa òfin rẹ̀, èyí ni òfin náà, àní bí ẹ ti gbọ́ ni àtètèkọ́ṣe, pé, kí ẹ̀yin rìn nínú rẹ̀.

77: 1Jh 2.22.Nítorí ẹlẹ́tàn púpọ̀ ti jáde wa sínú ayé, àwọn tí kò jẹ́wọ́ pé Jesu Kristi wá nínú ara. Èyí ni ẹlẹ́tàn àti aṣòdì sí Kristi. 8Ẹ kíyèsára yín, kí ẹ má ba à sọ iṣẹ́ tí ẹ tí ṣe nù, ṣùgbọ́n kí ẹ̀yin lè rí èrè kíkún gbà. 9Olúkúlùkù ẹni tí ó bá ń rú òfin tí kò si dúró nínú ẹ̀kọ́ Kristi, kò mọ Ọlọ́run. Ẹni tí ó bá dúró nínú ẹ̀kọ́, òun ni ó mọ Baba àti Ọmọ. 10Bí ẹnikẹ́ni bá tọ̀ yín wá, tí kò sì mu ẹ̀kọ́ yìí wá, ẹ má ṣe gbà á sí ilé, kí ẹ má sì ṣe kí i kú ààbọ̀. 11Nítorí ẹni tí ó bá kí kú ààbọ̀, ó ní ọwọ́ nínú iṣẹ́ búburú rẹ̀.

1212: 1Jh 1.4; 3Jh 13.Bí mo tilẹ̀ ní ohun púpọ̀ láti ṣe alábápín pẹ̀lú yín, síbẹ̀ èmi kò fẹ́ lo ìwé ìkọ̀wé àti jẹ́lú ìkọ̀wé. Ṣùgbọ́n èmi ní ìrètí láti tọ̀ yín wá àti láti bá a yín sọ̀rọ̀ lójúkojú, kí ayọ̀ yín bá à le è kún.

13Àwọn ọmọ arábìnrin rẹ àyànfẹ́ kí ọ.

Nueva Versión Internacional (Castilian)

2 Juan 1:1-13

1El anciano,

a la iglesia elegida y a sus miembros,1 la iglesia … miembros. Lit. la señora elegida y a sus hijos. a quienes amo en la verdad —y no solo yo, sino todos los que han conocido la verdad—, 2a causa de esa verdad que permanece en nosotros y que estará con nosotros para siempre:

3La gracia, la misericordia y la paz de Dios el Padre y de Jesucristo, el Hijo del Padre, estarán con nosotros en verdad y en amor.

4Me alegré muchísimo de encontrarme con algunos de vosotros4 vosotros. Lit. tus hijos. que estáis practicando la verdad, según el mandamiento que nos dio el Padre. 5Y ahora, hermanos, os ruego que nos amemos los unos a los otros. Y no es que os5 hermanos, os ruego … Y no es que os. Lit. señora, te ruego … Y no es que te. esté escribiendo un mandamiento nuevo, sino el que hemos tenido desde el principio. 6En esto consiste el amor: en que pongamos en práctica sus mandamientos. Y este es el mandamiento: que viváis en este amor, tal como lo habéis escuchado desde el principio.

7Es que han salido por el mundo muchos engañadores que no reconocen que Jesucristo ha venido en cuerpo humano. El que así actúa es el engañador y el anticristo. 8Cuidaos de no echar a perder el fruto de nuestro trabajo;8 el fruto de nuestro trabajo. Lit. lo que hemos trabajado. Var. lo que vosotros habéis trabajado. procurad, más bien, recibir la recompensa completa. 9Todo el que se descarría y no permanece en la enseñanza de Cristo no tiene a Dios; el que permanece en la enseñanza9 enseñanza. Var. enseñanza de Cristo. sí tiene al Padre y al Hijo. 10Si alguien os visita y no lleva esta enseñanza, no lo recibáis en casa ni le deis la bienvenida, 11pues quien le da la bienvenida se hace cómplice de sus malas obras.

12Aunque tengo muchas cosas que deciros, no he querido hacerlo por escrito, pues espero visitaros y hablar personalmente con vosotros, para que nuestra alegría sea completa.

13Los miembros de la comunidad elegida, hermana tuya, te13 Los miembros … te. Lit. Los hijos de tu hermana, la elegida, te. mandan saludos.