Ẹkun Jeremiah 1 – YCB & CARS

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Ẹkun Jeremiah 1:1-22

1Báwo ni ìlú ṣe jókòó nìkan,

nígbà kan tí ó sì kún fún ènìyàn!

Ó ti fìgbà kan jẹ́ ìlú olókìkí láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,

tí ó wà ní ipò opó,

Ẹni tí ó jẹ́ ọmọ ọbabìnrin láàrín ìlú

ni ó padà di ẹrú.

2Ọ̀gànjọ́ òru ni ó fi máa ń sọkún kíkorò

pẹ̀lú omijé ní ẹ̀rẹ̀kẹ́ rẹ̀ tí ó dúró sí ẹ̀rẹ̀kẹ́ rẹ̀.

Nínú gbogbo àwọn olólùfẹ́ rẹ̀

kò sí ọ̀kan nínú wọn láti rẹ̀ ẹ́ lẹ́kún.

Gbogbo àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ ti jọ̀wọ́ rẹ̀

wọ́n ti di alátakò rẹ̀.

3Lẹ́yìn ìjìyà àti ìpọ́njú nínú oko ẹrú,

Juda lọ sí àjò

Ó tẹ̀dó láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,

ṣùgbọ́n kò rí ibi ìsinmi.

Àwọn tí ó ń tẹ̀lé ká á mọ́

ibi tí kò ti le sá àsálà.

4Gbogbo ọ̀nà tí ó wọ Sioni ń ṣọ̀fọ̀,

nítorí ẹnìkan kò wá sí àjọ̀dún tí a yàn.

Gbogbo ẹnu-bodè rẹ̀ dahoro,

àwọn àlùfáà rẹ̀ kẹ́dùn,

àwọn wúńdíá rẹ̀ sì ń káàánú,

òun gan an wà ní ọkàn kíkorò.

5Àwọn aninilára rẹ̀ gbogbo di olúwa rẹ̀,

nǹkan sì rọrùn fún àwọn ọ̀tá rẹ̀,

Olúwa ti fún un ní ìjìyà tó tọ́

nítorí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.

Àwọn ẹ̀ṣọ́ wẹ́wẹ́ rẹ̀ lọ sí oko ẹrú,

ìgbèkùn níwájú àwọn ọ̀tá.

6Gbogbo ẹwà ti di ohun ìgbàgbé

kúrò lọ́dọ̀ ọmọbìnrin Sioni.

Àwọn ìjòyè rẹ̀ dàbí i àgbọ̀nrín

tí kò rí ewé tútù jẹ;

nínú àárẹ̀ wọ́n sáré

níwájú ẹni tí ó ń lé wọn.

7Ní ọjọ́ ìpọ́njú àti àrìnká rẹ̀ ni

Jerusalẹmu rántí àwọn ohun ìní dáradára rẹ̀

tí ó jẹ́ tirẹ̀ ní ọjọ́ pípẹ́.

Nígbà tí àwọn ènìyàn rẹ̀ ṣubú ṣọ́wọ́ àwọn ọ̀tá,

kò sì ṣí olùrànlọ́wọ́ fún un.

Àwọn ọ̀tá rẹ̀ wò ó

wọ́n sì ń fi ìparun rẹ̀ ṣẹlẹ́yà.

8Jerusalẹmu sì ti dẹ́ṣẹ̀ púpọ̀

ó sì ti di aláìmọ́.

Àwọn tí ó ń tẹríba fún un sì kẹ́gàn rẹ̀,

nítorí wọ́n ti rí ìhòhò rẹ̀;

ó kérora fúnrarẹ̀,

ó sì lọ kúrò.

9Ìdọ̀tí wà ní etí aṣọ rẹ̀,

bẹ́ẹ̀ ni kò wo ọjọ́ iwájú rẹ̀,

Ìṣubú rẹ̀ ya ni lẹ́nu;

olùtùnú kò sì ṣí fún un.

“Wo ìpọ́njú mi, Olúwa,

nítorí àwọn ọ̀tá ti borí.”

10Ọ̀tá ti gbọ́wọ́ lé

gbogbo ìní rẹ;

o rí pé àwọn orílẹ̀-èdè

tí wọ́n wọ ibi mímọ́ rẹ—

àwọn tí o ti kọ̀sílẹ̀

láti wọ ìpéjọpọ̀ rẹ.

11Àwọn ènìyàn rẹ̀ ń kérora

bí wọ́n ti ń wá oúnjẹ;

wọ́n fi ohun ìní wọn ṣe pàṣípàrọ̀ oúnjẹ

láti mú wọn wà láààyè.

“Wò ó, Olúwa, kí o sì rò ó,

nítorí a kọ̀ mí sílẹ̀.”

12“Kò ha jẹ́ nǹkan kan sí i yín?

Gbogbo ẹ̀yin tí ń rékọjá,

Ǹjẹ́ ẹnìkan ń jìyà bí èmi ti ń jìyà

tí a fi fún mi, ti

Olúwa mú wá fún mi

ní ọjọ́ ìbínú gbígbóná rẹ̀.

13“Ó rán iná láti òkè

sọ̀kalẹ̀ sínú egungun ara mi.

Ó dẹ àwọ̀n fún ẹsẹ̀ mi,

ó sì yí mi padà.

Ó ti pa mí lára

mó ń kú lọ ní gbogbo ọjọ́.

14“Ẹ̀ṣẹ̀ mi ti di sísopọ̀ sí àjàgà;

ọwọ́ rẹ̀ ni a fi hun ún papọ̀.

Wọ́n ti yí ọrùn mi ká

Olúwa sì ti dín agbára mi kù.

Ó sì ti fi mí lé

àwọn tí n kò le dojúkọ lọ́wọ́.

15“Olúwa kọ

àwọn akọni mi sílẹ̀,

ó rán àwọn ológun lòdì sí mi

kí wọn pa àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin mi run.

Nínú ìfúntí wáìnì rẹ̀ Olúwa tẹ́

àwọn ọ̀dọ́mọbìnrin Juda.

16“Ìdí nìyí tí mo fi ń sọkún

tí omijé sì ń dà lójú mi,

Olùtùnú àti ẹni tí ó le mú ọkàn mi sọjí jìnnà sí mi,

kò sí ẹni tí yóò dá ẹ̀mí mi padà.

Àwọn ọmọ mi di aláìní

nítorí ọ̀tá ti borí.”

17Sioni na ọwọ́ jáde,

ṣùgbọ́n kò sí olùtùnú fún un.

Olúwa ti pàṣẹ fún Jakọbu

pé àwọn ará ilé rẹ̀ di ọ̀tá fún un

Jerusalẹmu ti di

ohun aláìmọ́ láàrín wọn.

18“Olóòtítọ́ ni Olúwa,

ṣùgbọ́n mo ṣọ̀tẹ̀ sí àṣẹ rẹ̀.

Ẹ gbọ́, gbogbo ènìyàn;

ẹ wò mí wò ìyà mi.

Gbogbo ọ̀dọ́mọkùnrin àti ọ̀dọ́mọbìnrin mi

ni a ti kó lọ sí ìgbèkùn.

19“Mo pe àwọn ọ̀rẹ́ mi

ṣùgbọ́n wọ́n dà mí.

Àwọn olórí àlùfáà àti àgbàgbà mi

ṣègbé sínú ìlú

nígbà tí wọ́n ń wá oúnjẹ

tí yóò mú wọn wà láààyè.

20Olúwa, wò ó, bí mo ti wà nínú ìnira!

Tí mo sì ń jẹ̀rora nínú mi,

ìdààmú dé bá ọkàn mi

nítorí pé a ti ṣọ̀tẹ̀ sí mi gidigidi.

Ní gbangba ni idà ń parun;

ikú wà nínú ilé pẹ̀lú.

21“Àwọn ènìyàn ti gbọ́ ìrora mi,

ṣùgbọ́n kò sí olùtùnú fún mi.

Àwọn ọ̀tá mi ti gbọ́ ìparun mi;

wọ́n yọ̀ sí ohun tí o ṣe.

Kí o mú ọjọ́ tí o ti kéde,

kí wọ́n le dàbí tèmi.

22“Jẹ́ kí ìwà ìkà wọn wá síwájú rẹ;

jẹ wọ́n ní yà

bí o ṣe jẹ mí ní yà

nítorí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ mi.

Ìrora mi pọ̀

ọkàn mi sì rẹ̀wẹ̀sì.”

Священное Писание

Плач 1:1-22

Иерусалим – одинокая вдова

1Как одиноко стоит столица,

что некогда была многолюдной!

Она стала как вдова,

а была великой среди народов,

была царицей над областями,

но стала рабыней.

2Горько плачет она ночью,

и слёзы текут по её щекам.

Нет у неё утешителя

среди всех возлюбленных1:2 Возлюбленные – союзники Иудеи, которые предали её, и их боги. Также в ст. 19. её.

Все друзья изменили ей

и стали врагами.

3Иудея пошла в изгнание

после бед и тяжкого рабства.

Поселилась она среди других народов,

но не нашла покоя.

Все её преследователи настигли её

посреди бедствия.

4Дороги в Иерусалим1:4 Букв.: «Сион». плачут,

потому что никто не идёт на праздник.

Все ворота столицы опустели,

стонут священнослужители её,

девушки печальны,

горько и ей самой.

5Враги правят ею,

неприятели её благоденствуют.

Горе послал ей Вечный1:5 Вечный – на языке оригинала: «Яхве». Под этим именем Всевышний открылся Мусе и народу Исраила (см. Исх. 3:13-15). См. пояснительный словарь.

из-за множества её беззаконий.

Дети её пошли в плен,

враг гонит их перед собой.

6Всё великолепие покинуло дочь Сиона1:6 То есть Иерусалим..

Вожди её подобны оленям, не находящим пастбища;

обессиленные они бегут впереди погонщика.

7В дни своих бедствий и скитаний

вспомнила столица о всех драгоценностях,

которые были у неё в прежние дни.

Когда народ её попал в руки врага,

никто не помог ей;

враги смотрели на неё

и смеялись над её поражением.

8Ужасно согрешила столица,

поэтому она и стала нечистой.

Все, кто прославлял её, теперь презирают,

потому что увидели её наготу.

Да и сама она вздыхает и отворачивается;

9её нечистота замарала ей подол.

И так как она не задумывалась о будущем,

падение её было ошеломительным,

и не было у неё утешителя.

– О Вечный, взгляни на моё страдание,

ведь враг торжествует!

10Враг похитил у неё всё самое ценное;

она видит, как в её святилище входят язычники,

те, кому Ты запретил вступать в Твоё собрание.

11Весь народ её стонет в поисках хлеба,

отдаёт драгоценности свои за пищу,

лишь бы жизнь сохранить.

– О Вечный, обрати Твой взор

и посмотри, как я унижена!

Вопль Иерусалима

12– Неужели это не трогает вас, все проходящие мимо?

Взгляните и посмотрите,

есть ли страдание, подобное моему страданию,

которое постигло меня,

которое Вечный послал на меня

в день Своего пылающего гнева?

13Свыше Он послал огонь,

послал его в кости мои.

Он раскинул сеть для ног моих,

опрокинул меня.

Он опустошил меня

и наполнил дни мои болезнью.

14Беззакония мои Он взял

и, связав их, сделал из них ярмо.

Владыка возложил его на шею мою,

чем ослабил силы мои.

Он отдал меня в руки тех,

кому я не могу противостоять.

15Владыка низложил среди меня

всех сильных моих,

собрал против меня войска,

чтобы истребить моих юношей;

как в давильне, истоптал Владыка

девственную дочь Иуды1:15 То есть народ Иудеи..

16Вот почему я плачу

и из глаз моих потоками льются слёзы.

Рядом нет никого, кто бы утешил меня,

оживил бы душу мою.

Дети мои разорены,

потому что враг одолел их.

17Сион простирает руки свои,

но нет никого, кто бы утешил его.

Вечный повелел окружающим народам

враждовать с Исраилом1:17 Букв.: «с Якубом». Исраильтяне были потомками Якуба, которому Всевышний дал новое имя – Исраил (см. Нач. 32:27-28).;

Иерусалим стал

мерзостью среди них.

18– Праведен Вечный,

а я была непокорна слову Его.

Послушайте, все народы,

и взгляните на страдание моё.

Девушки и юноши мои

пошли в плен.

19Звала я возлюбленных моих,

но они меня предали.

Священнослужители и старцы мои

умирали в городе,

ища себе пищи,

чтобы сохранить себе жизнь.

20Взгляни, Вечный, как я страдаю:

душа моя мается

и сердце потеряло покой,

потому что я упорно противилась Тебе.

Снаружи меч лишил меня детей,

а внутри – поселилась смерть.

21Люди услышали стоны мои,

но никто меня не утешит.

Все враги мои услышали о бедствии моём

и были рады тому, что Ты сделал со мною.

Пусть же наступит день,

объявленный Тобой,

когда с ними случится то же,

что и со мной.

22Пусть все их злодеяния предстанут пред Тобой,

и поступи с ними так же,

как Ты поступил со мною

за все грехи мои,

потому что многочисленны стоны мои,

и изнемогает сердце моё.