Ìfihàn 1 – YCB & PCB

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Ìfihàn 1:1-20

Ọ̀rọ̀ ìṣáájú

1Ìfihàn ti Jesu Kristi, tí Ọlọ́run fi fún un, láti fihàn fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, ohun tí kò le ṣàìṣẹ ní lọ́ọ́lọ́ọ́; ó sì ránṣẹ́, ó sì fi í hàn láti ọwọ́ angẹli rẹ̀ wá fún Johanu, ìránṣẹ́ rẹ̀: 2Ẹni tí ó jẹ́rìí ohun gbogbo tí ó rí—èyí ì ni ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, àti ẹ̀rí ti Jesu Kristi. 3Ẹni ìbùkún ni ẹni tí ń kà, àti àwọn tí ó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ ìsọtẹ́lẹ̀ yìí, tí ó sì ń pa nǹkan wọ̀n-ọn-nì tí a kọ sínú rẹ̀ mọ́: nítorí ìgbà kù sí dẹ̀dẹ̀.

Ọ̀rọ̀ ìkíni àti ìyìn

41.4: Ek 3.14.Johanu,

Sí àwọn ìjọ méje tí ń bẹ ní Asia:

Oore-ọ̀fẹ́ fún yín, àti àlàáfíà, láti ọ̀dọ̀ ẹni tí ó ń bẹ, tí ó sì ti wà, tí ó sì ń bọ̀ wá; àti láti ọ̀dọ̀ àwọn ẹ̀mí méje tí ń bẹ níwájú ìtẹ́ rẹ̀; 51.5: Sm 89.27.àti láti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi, ẹlẹ́rìí olóòtítọ́, àkọ́bí nínú àwọn òkú, àti aláṣẹ àwọn ọba ayé.

Ẹni tí ó fẹ́ wa, ẹni tí ó gbà wá kúrò lọ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wa nípa ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, 61.6: Ek 19.6; Isa 61.6.tí ó sì ti fi wá jẹ ọba àti àlùfáà láti sin Ọlọ́run àti Baba rẹ; tirẹ̀ ni ògo àti ìjọba láé àti láéláé. Àmín.

71.7: Da 7.13; Mt 24.30; Mk 14.62; Sk 12.10.Kíyèsi i, o ń bọ̀ nínú àwọsánmọ̀;

gbogbo ojú ni yóò sì rí i,

àti àwọn tí ó gún un ní ọ̀kọ̀ pẹ̀lú;

àti gbogbo orílẹ̀-èdè ayé ni yóò sì máa pohùnréré ẹkún nítorí rẹ̀.

Bẹ́ẹ̀ náà ni! Àmín.

81.8: Ek 3.14. “Èmi ni Alfa àti Omega,” ni Olúwa Ọlọ́run wí, “ẹni tí ó ń bẹ, tí ó ti wà, tí ó sì ń bọ̀ wá, alágbára.”

Ọ̀kan gẹ́gẹ́ bí Ọmọ ènìyàn

9Èmi, Johanu, arákùnrin yín àti alábápín pẹ̀lú yín nínú wàhálà àti ìjọba àti sùúrù tí ń bẹ nínú Jesu, wà ní erékúṣù tí a ń pè ní Patmo, nítorí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, àti nítorí ẹ̀rí Jesu Kristi. 10Mo wà nínú Ẹ̀mí ní ọjọ́ Olúwa, mo sì gbọ́ ohùn ńlá kan lẹ́yìn mi, bí ìró ìpè, 11Ó ń wí pé, “Kọ́ ìwé rẹ̀, ohun tí ìwọ rí, kí ó sí fi ránṣẹ́ sí àwọn ìjọ méje; sí Efesu, àti sí Smirna, àti sí Pargamu, àti sí Tiatira, àti sí Sardi, àti sí Filadelfia, àti sí Laodikea.”

12Mo sì yí padà láti wo ohùn tí ń bá mi sọ̀rọ̀. Nígbà tí mo yípadà, mo rí ọ̀pá fìtílà wúrà méje; 131.13: Da 7.13; 10.5.àti láàrín àwọn ọ̀pá fìtílà náà, ẹnìkan tí ó dàbí “ọmọ ènìyàn,” tí a wọ̀ ní aṣọ tí ó kanlẹ̀ dé ẹsẹ̀, tí a sì fi àmùrè wúrà dì ní ẹ̀gbẹ́. 14Orí rẹ̀ àti irun rẹ̀ funfun bí ẹ̀gbọ̀n òwú, ó funfun bí yìnyín; ojú rẹ̀ sì dàbí, ọwọ́ iná; 151.15: El 1.24.Ẹsẹ̀ rẹ̀ sì dàbí idẹ dáradára, bí ẹni pé a dà á nínú ìléru; ohùn rẹ̀ sì dàbí ìró omi púpọ̀. 161.16: Ek 34.29.Ó sì ní ìràwọ̀ méje ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀; àti láti ẹnu rẹ̀ wá ni idà olójú méjì mímú ti jáde: Ojú rẹ̀ sì dàbí oòrùn tí ó ń fi agbára rẹ̀ hàn.

171.17: Isa 44.2,6.Nígbà tí mo rí i, mo wólẹ̀ ní ẹsẹ̀ rẹ̀ bí ẹni tí ó kú. Ó sì fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ lé mi, ó ń wí fún mi pé, “Má ṣe bẹ̀rù. Èmi ni ẹni ìṣáájú àti ẹni ìkẹyìn. 18Èmi ni ẹni tí ó ń bẹ láààyè, tí ó sì ti kú; sì kíyèsi i, èmi sì ń bẹ láààyè sí i títí láé! Mo sì ní kọ́kọ́rọ́ ikú àti ti ipò òkú lọ́wọ́.

19“Kọ̀wé nítorí náà ohun tí ìwọ ti rí, àti ti ohun tí ń bẹ, àti ti ohun tí yóò hù lẹ́yìn èyí; 20ohun ìjìnlẹ̀ tí ìràwọ̀ méje náà tí ìwọ rí ní ọwọ́ ọ̀tún mi, àti ọ̀pá wúrà fìtílà méje náà. Ìràwọ̀ méje ni àwọn angẹli ìjọ méje náà: àti ọ̀pá fìtílà méje náà ní àwọn ìjọ méje.

Persian Contemporary Bible

مکاشفه 1:1-20

مقدمه

1در اين كتاب از رويدادهای آينده پرده برمی‌دارد، رويدادهايی كه بزودی رخ خواهد داد. خدا به مسيح اجازه داد تا اين وقايع را در يک رؤيا بر خادم خود «يوحنا» آشكار سازد. آنگاه فرشته‌ای آمد و معنی آن را برای او بازگو كرد. 2يوحنا نيز تمام سخنان خدا و عيسی مسيح و هر آنچه را كه خود ديد و شنيد، به نگارش درآورد.

3خوشا به حال كسی كه اين پيشگويی‌ها را برای ديگران بخواند؛ و خوشا به حال آنان كه به آن گوش فرا دهند، زيرا زمان وقوع اين رويدادها چندان دور نيست.

سلام يوحنا بر هفت کليسا

4از طرف يوحنا، به هفت كليسا در ايالت آسيا. فيض و آرامش بر شما باد، از جانب پروردگاری كه هست و بود و خواهد آمد، و از جانب روح هفتگانهٔ خدا كه در پيشگاه تخت الهی است، 5و از جانب عيسی مسيح كه تمام حقيقت را به طور كامل بر ما آشكار می‌فرمايد. مسيح نخستين كسی است كه پس از مرگ زنده شد و هرگز نخواهد مرد، و برتر از تمام پادشاهان اين جهان است. سپاس و ستايش بر او كه ما را محبت می‌نمايد و با خون خود ما را شست و از گناهانمان طاهر ساخت؛ 6او ما را در ملكوت و سلطنت خود، به مقام كاهن منصوب كرده تا خدا يعنی پدر او را خدمت نماييم. او را تا ابد قدرت و جلال باد! آمين.

7بنگريد! او سوار بر ابرها می‌آيد. هر چشمی او را خواهد ديد؛ حتی آنانی كه به پهلوی او نيزه زدند، او را خواهند ديد؛ و تمام قومهای جهان از شدت وحشت و اندوه خواهند گريست. بلی، آمين! بگذار چنين باشد. 8خدا می‌فرمايد: «من الف و يا هستم. من ابتدا و انتها هستم.» اين را خداوندی می‌فرمايد كه صاحب تمام قدرتهاست، و هست و بود و باز خواهد آمد.

مسيح بر يوحنا آشكار می‌شود

9من، يوحنا، كه اين نامه را برای شما می‌نويسم، مانند شما در راه خداوند رنج می‌كشم. اما او به ما صبر و تحمل عطا فرموده و ما را در ملكوت خود سهيم نموده است.

من به علت اعلام پيغام انجيل و بشارت دربارهٔ مسيح، به جزيرهٔ پطموس تبعيد شدم. 10روز خداوند بود و من در حال عبادت بودم كه روح خدا مرا فرو گرفت. ناگهان از پشت سر خود، صدايی بلند همچون صدای شيپور شنيدم، 11كه می‌گفت: «من الف و يا هستم. من ابتدا و انتها هستم. هر چه می‌بينی، در نامه‌ای بنويس و آن را برای هفت كليسا بفرست، يعنی برای كليساهای اَفَسُس، اِزمير، پرغامه، طياتيرا، سارد، فيلادلفيه و لائوديكيه.»

12هنگامی كه برگشتم تا كسی را كه با من سخن می‌گفت ببينم، در پشت سر خود هفت شمعدان طلا ديدم. 13در ميان شمعدانها، مردی ديدم شبيه «پسر انسان» كه ردايی بلند بر تن داشت و كمربندی طلايی دور سينه‌اش بود. 14سر و موی او سفيد بود چون برف و پشم، و چشمانش تيز و نافذ بود همچون شعله‌های آتش. 15پايهای او می‌درخشيد، مانند مسی كه در آتش صيقل داده باشند. صدای او مثل آبشار طنين‌افكن بود. 16در دست راست او، هفت ستاره بود، و شمشير دو دمِ تيزی هم در دهانش قرار داشت. صورت او همچون خورشيد نيمروز می‌درخشيد.

17‏-18وقتی چشمم به او افتاد، مانند مرده جلو پای او افتادم. اما او دست راست خود را بر من گذاشت و فرمود: «نترس! من ابتدا و انتها هستم! من زنده بودم و مُردم، و حال تا به ابد زنده‌ام، و كليدهای مرگ و عالم مردگان را در دست دارم. 19آنچه را ديدی و آنچه را كه نشان خواهم داد، همه را بنويس. 20معنی هفت ستاره‌ای كه در دست راست من ديدی و همچنين هفت شمعدان طلا اينست: هفت ستاره، رهبران هفت كليسا هستند، و هفت شمعدان، خود هفت كليسا می‌باشند.»