Cartea I
(Psalmii 1–41)
Psalmul 1
1Ferice de omul care nu se duce la sfatul celor răi,
nu se oprește pe calea celor păcătoși
și nu se așază pe scaunul celor batjocoritori!
2Ci își găsește plăcerea în Legea Domnului
și zi și noapte cugetă la Legea Lui.
3El este ca un pom sădit lângă niște izvoare de apă,
care‑și dă rodul la vremea lui
și ale cărui frunze nu se veștejesc.
El prosperă în tot ceea ce face!
4Cei răi însă nu sunt așa,
ci ei sunt ca pleava
spulberată de vânt.
5De aceea cei răi nu pot sta în picioare la judecată
și nici cei păcătoși în comunitatea celor drepți.
6Căci Domnul cunoaște calea celor drepți;
calea celor răi însă duce la pieire.
ÌWÉ KÌN-ÍN-NÍ
Saamu 1–41
Saamu 1
11.1-3: Jr 17.7-8.Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà,
tí kò rìn ní ìmọ̀ àwọn ènìyàn búburú,
ti kò dúró ní ọ̀nà àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,
tàbí tí kò sì jókòó ní ibùjókòó àwọn ẹlẹ́gàn.
2Ṣùgbọ́n ayọ̀ inú rẹ̀ wà nínú òfin Olúwa
àti nínú òfin rẹ̀ ni ó ń ṣe àṣàrò ní ọ̀sán àti òru.
3Ó dàbí igi tí a gbìn sí etí odò tí ń sàn,
tí ń so èso rẹ̀ jáde ní àkókò rẹ̀
tí ewé rẹ̀ kì yóò rẹ̀.
Ohunkóhun tí ó dáwọ́lé, ni yóò máa yọrí sí rere.
4Kò le rí bẹ́ẹ̀ fún àwọn ènìyàn búburú!
Wọn yóò dàbí ìyàngbò ọkà
tí afẹ́fẹ́ ń fẹ́ dànù.
5Nítorí náà àwọn ènìyàn búburú kì yóò le è dìde dúró ní ìdájọ́,
bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ kì yóò le è dúró ní àwùjọ àwọn olódodo.
6Nítorí Olúwa ń ṣọ́ ọ̀nà àwọn olódodo,
ṣùgbọ́n ọ̀nà àwọn ènìyàn búburú ni yóò ṣègbé.