Psalm 15 – NIRV & YCB

New International Reader’s Version

Psalm 15:1-5

Psalm 15

A psalm of David.

1Lord, who can live in your sacred tent?

Who can stay on your holy mountain?

2Anyone who lives without blame

and does what is right.

They speak the truth from their heart.

3They don’t tell lies about other people.

They don’t do wrong to their neighbors.

They don’t say anything bad about them.

4They hate evil people.

But they honor those who have respect for the Lord.

They keep their promises even when it hurts.

They do not change their mind.

5They lend their money to poor people without charging interest.

They don’t accept money to harm those who aren’t guilty.

Anyone who lives like that

will always be secure.

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 15:1-5

Saamu 15

Saamu ti Dafidi

1Olúwa, ta ni yóò máa ṣe àtìpó nínú àgọ́ rẹ?

Ta ni yóò máa gbé ní òkè mímọ́ rẹ?

2Ẹni tí ń rìn déédé

tí ó sì ń sọ òtítọ́,

láti inú ọkàn rẹ̀;

3tí kò fi ahọ́n rẹ̀ sọ̀rọ̀ ẹni lẹ́yìn,

tí kò ṣe ibi sí aládùúgbò rẹ̀

tí kò sì sọ̀rọ̀ ẹ̀gàn sí ẹnìkejì rẹ̀,

4ní ojú ẹni tí ènìyànkénìyàn di gígàn

ṣùgbọ́n ó bọ̀wọ̀ fún àwọn tí ó bẹ̀rù Olúwa,

Ẹni tí ó búra sí ibi ara rẹ̀

àní tí kò sì yípadà,

5tí ó ń yá ni lówó láìsí èlé

tí kò sì gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ lòdì sí aláìlẹ́ṣẹ̀.

Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe èyí

ni a kì yóò mì láéláé.