መዝሙር 57 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

መዝሙር 57:1-11

መዝሙር 57

በጨካኝ ጠላቶች ዘንድ

57፥7-11 ተጓ ምብ – መዝ 108፥1-5

ለመዘምራን አለቃ፤ “አታጥፋ” በሚለው ቅኝት የሚዘመር፤ ከሳኦል ፊት ሸሽቶ በዋሻ በነበረበት ጊዜ፤ የዳዊት ቅኔ57 ርእሱ የሥነ ጽሑፉን ቅርጽ ወይም የመዝሙሩን ሁኔታ የሚያሳይ ሊሆን ይችላል።

1ማረኝ፤ እግዚአብሔር ሆይ፤ ማረኝ፤

ነፍሴ አንተን መጠጊያ አድርጋለችና፤

በክንፎችህ ሥር እጠለላለሁ።

2ለእኔ ያሰበውን ወደሚፈጽምልኝ አምላክ፣

ወደ ልዑል እግዚአብሔር እጮኻለሁ።

3ከሰማይ ልኮ ያድነኛል፤

የረገጡኝን ያዋርዳቸዋል፤ ሴላ

እግዚአብሔር ምሕረቱንና ታማኝነቱን ይልካል።

4ነፍሴ በአንበሶች ተከብባለች፤

በሚዘነጣጥሉ አራዊት መካከል ወድቄአለሁ፤

እነዚህም፣ ጥርሳቸው ጦርና ፍላጻ፣

ምላሳቸውም የተሳለ ሰይፍ የሆኑ ሰዎች ናቸው።

5እግዚአብሔር ሆይ፤ ከሰማያት በላይ ከፍ ከፍ በል፤

ክብርህም በምድር ሁሉ ላይ ትስፈን።

6ለእግሬ ወጥመድን ዘረጉ፤

ነፍሴንም አጐበጧት፤

በመተላለፊያዬ ላይ ጕድጓድ ቈፈሩ፤

ነገር ግን ራሳቸው ገቡበት። ሴላ

7እግዚአብሔር ሆይ፤ ልቤ ጽኑ ነው፤

ልቤ ጽኑ ነው፤

እቀኛለሁ፤ አዜማለሁ።

8ነፍሴ ሆይ፤ ንቂ!

በገናና መሰንቆም ተነሡ

እኔም በማለዳ እነሣለሁ።

9ጌታ ሆይ፤ በሕዝቦች መካከል አመሰግንሃለሁ፤

በሰዎችም መካከል እዘምርልሃለሁ፤

10ምሕረትህ እስከ ሰማያት ከፍ ብላለችና፤

ታማኝነትህም እስከ ደመናት ትደርሳለች።

11እግዚአብሔር ሆይ፤ ከሰማያት በላይ ከፍ ከፍ በል፤

ክብርህም በምድር ሁሉ ላይ ትስፈን።

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 57:1-11

Saamu 57

Fún adarí orin. Ní ohùn “Má ṣe parun.” Ti Dafidi. Miktamu. Nígbà tí ó sá níwájú Saulu lọ sínú ihò òkúta.

1Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run, ṣàánú fún mi,

nítorí nínú rẹ ni ààbò ọkàn mí wà.

Èmi o fi ààbò mí sí ibi ìyẹ́ apá rẹ

títí tí ewu yóò fi kọjá lọ.

2Mo kígbe sókè sí Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo jùlọ,

sí Ọlọ́run tó ń pa májẹ̀mú rẹ̀ mọ́ fún mi.

3Òun yóò ránṣẹ́ láti ọ̀run wá,

yóò sì gbà mí, bí ẹni tí ń fẹ́ gbé mi mì

tilẹ̀ ń kẹ́gàn mi.

Ọlọ́run yóò rán àánú rẹ̀ àti òdodo rẹ̀ jáde.

4Mo wà ní àárín àwọn kìnnìún;

mo dùbúlẹ̀ ni abẹ́ àwọn ẹ̀dá búburú,

àwọn ènìyàn tí eyín wọn dàbí ọ̀kọ̀ àti ọfà

ẹni tí ahọ́n rẹ̀ jẹ́ idà mímú.

5Kí a yìn ọ́ Ọlọ́run, ju ọ̀run lọ,

kí ògo rẹ kò ju ti gbogbo ayé lọ.

6Wọ́n ti ta àwọ̀n sílẹ̀ fún ẹsẹ̀ mi:

a tẹ orí ọkàn mi ba nínú ìtìjú,

wọ́n gbẹ́ kòtò sí ọ̀nà mi:

ṣùgbọ́n wọ́n ti jì síbẹ̀ fún ara wọn.

757.7-11: Sm 108.1-5.Ọkàn mi ti múra Ọlọ́run;

ọkàn mi ti múra, èmi ó kọrin, èmi ó si máa kọrin ìyìn.

8Jí, ìwọ ọkàn mi!

Jí, ohun orin èlò àti dùùrù!

Èmi tìkára mi, yóò sì jí ní kùtùkùtù.

9Èmi ó máa yìn ọ́, Olúwa, láàrín àwọn orílẹ̀-èdè;

èmi ó máa kọrin sí ọ láàrín àwọn ènìyàn.

10Nítorí títóbi ní ìfẹ́ rẹ, tí ó dé ọ̀run;

òtítọ́ rẹ tàn dé àwọsánmọ̀.

11Gbígbéga ni ọ́, Ọlọ́run, ju àwọn ọ̀run lọ;

kí ògo rẹ kí ó ju gbogbo ayé lọ.