ሆሴዕ 12 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

ሆሴዕ 12:1-14

1ኤፍሬም የነፋስ እረኛ ነው፤

ቀኑን ሙሉ የምሥራቅን ነፋስ ይከተላል፤

ሐሰትንና ዐመፅን ያበዛል።

ከአሦር ጋር ቃል ኪዳን ያደርጋል፤

የወይራ ዘይትንም ወደ ግብፅ ይልካል።

2እግዚአብሔር በይሁዳ ላይ የሚያቀርበው ክስ አለው፤

ያዕቆብን12፥2 ያዕቆብ ማለት ተረከዝ ይይዛል ማለት ሲሆን፣ ያታልላል ለማለት ዘይቤአዊ አገላለጽ ነው። እንደ መንገዱ ይቀጣዋል፤

እንደ ሥራውም ይከፍለዋል።

3በማሕፀን ሳለ የወንድሙን ተረከዝ ያዘ፤

ሙሉ ሰውም ሲሆን ከአምላክ ጋር ታገለ።

4ከመልአኩም ጋር ታገለ፤ አሸነፈውም፤

በፊቱ ሞገስን ለማግኘት አልቅሶ ለመነው፣

እርሱንም በቤቴል አገኘው፤

በዚያም ከእርሱ ጋር ተነጋገረ፤

5እርሱም ሁሉን የሚገዛ አምላክ እግዚአብሔር

የሚታወቅበት ስሙም እግዚአብሔር ነው።

6ስለዚህ ወደ አምላክህ ተመለስ፤

ፍቅርንና ፍትሕን ጠብቅ፤

ዘወትርም በአምላክህ ታመን።

7ነጋዴው በሐሰተኛ ሚዛን ይሸጣል፤

ማጭበርበርንም ይወድዳል።

8ኤፍሬም እንዲህ እያለ ይታበያል፤

“እኔ ባለጠጋ ነኝ፤ ሀብታምም ሆኛለሁ፤

ይህ ሁሉ ሀብት እያለኝ፣

ምንም ዐይነት በደል ወይም ኀጢአት አያገኙብኝም።”

9“ከግብፅ ምድር ያወጣኋችሁ፣12፥9 ወይም በግብፅ ከነበራችሁበት ጊዜ አንሥቶ አምላካችሁ እግዚአብሔር እኔ ነኝ፤

በዓመት በዓላችሁ ቀን ታደርጉ እንደ ነበረው ሁሉ፣

እንደ ገና በድንኳኖች እንድትቀመጡ

አደርጋችኋለሁ።

10ለነቢያት ተናገርሁ፤

ራእይንም አበዛሁላቸው፤

በእነርሱም በኩል በምሳሌ ተናገርሁ።”

11ገለዓድ ክፉ ነው፤

ሕዝቡም ከንቱ ናቸው፤

ኮርማዎችን በጌልገላ ይሠዋሉን?

መሠዊያዎቻቸው በታረሰ መሬት ላይ እንዳለ፣

የድንጋይ ክምር ይሆናሉ።

12ያዕቆብ ወደ ሶርያ12፥12 ሰሜን መስጴጦምያን ያመለክታል ሸሸ፤

እስራኤል ሚስት ለማግኘት ሲል አገለገለ፤

ዋጋዋንም ለመክፈል በጎችን ጠበቀ።

13እግዚአብሔር በነቢይ አማካይነት እስራኤልን ከግብፅ አወጣ፤

በነቢይም በኩል ተንከባከበው።

14ኤፍሬም ግን ክፉኛ አስቈጣው፤

ጌታውም የደም አፍሳሽነቱን በደል በላዩ ላይ ያደርግበታል፤

ስለ ንቀቱም የሚገባውን ይከፍለዋል።

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Hosea 12:1-14

1Efraimu ń jẹ afẹ́fẹ́;

o ń lépa afẹ́fẹ́ ìwọ̀-oòrùn ní gbogbo ọjọ́.

O sì ń gbèrú nínú irọ́

o dá májẹ̀mú pẹ̀lú Asiria

o sì fi òróró olifi ránṣẹ́ sí Ejibiti.

2Olúwa ní ẹjọ́ kan tí yóò bá Juda rò,

yóò fì ìyà jẹ Jakọbu gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ̀

yóò sì sán fún un gẹ́gẹ́ bí i ìṣe rẹ̀.

3Láti inú oyún ni ó ti di arákùnrin rẹ̀ mú ni gìgísẹ̀,

àti nípa ipá rẹ̀ ó ni agbára pẹ̀lú Ọlọ́run

4Ó bá angẹli ja ìjàkadì, ó sì borí rẹ̀

o sọkún, ó sì bẹ̀bẹ̀ fún ojúrere rẹ̀

Ó bá Olúwa ní Beteli

Ó sì bá a sọ̀rọ̀ níbẹ̀,

5àní Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun;

Olúwa ni orúkọ ìrántí rẹ̀

6Ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ padà sọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀;

di ìfẹ́ àti ìdájọ́ òdodo mú

kí ẹ sì dúró de Ọlọ́run yín nígbà gbogbo.

7Oníṣòwò ń lo òṣùwọ̀n èké

o fẹ́ràn láti rẹ́ ni jẹ.

812.8: If 3.17.Efraimu gbéraga,

“Èmi ní ìní fún ara mi, mo sì ti di ọlọ́rọ̀,

pẹ̀lú gbogbo ọrọ̀ mi yìí, wọn kò le ká àìṣedéédéé

tàbí ẹ̀ṣẹ̀ kankan mọ́ mi lọ́wọ́.”

9“Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ;

ẹni tí ó mu ọ jáde wá láti ilẹ̀ Ejibiti;

èmi yóò tún mú yín gbé nínú àgọ́

bí i ọjọ́ àjọ̀dún tí a yàn wọ̀n-ọn-nì

10Mo sọ fún àwọn wòlíì,

mo fi ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìran hàn wọ́n

mo sì pa òwe láti ẹnu wòlíì wọn.”

11Gileadi ha burú bí?

Àwọn ènìyàn rẹ̀ jẹ́ asán.

Ǹjẹ́ wọ́n ń fi akọ màlúù rú ẹbọ ní Gilgali?

Gbogbo pẹpẹ wọ́n sì dàbí ebè

nínú aporo oko.

12Jakọbu sálọ si orílẹ̀-èdè Aramu;

Israẹli sìn kí o tó fẹ́ ìyàwó

ó ṣe ìtọ́jú ẹran láti fi san owó ìyàwó.

13Olúwa lo wòlíì kan láti mú Israẹli jáde wá láti Ejibiti,

nípasẹ̀ wòlíì kan ó ṣe ìtọ́jú rẹ̀.

14Ṣùgbọ́n Efraimu ti mú un bínú gidigidi;

Olúwa rẹ̀ yóò sì fi ẹ̀bi ìtàjẹ̀ sílẹ̀ sí orí rẹ̀

òun yóò sì san án padà fún un nítorí ìwà ẹ̀gàn an rẹ̀.