Ezara 10 – GKY & YCB

Holy Bible in Gĩkũyũ

Ezara 10:1-44

Andũ Kuumbũra Mehia

110:1 2Maũ 20:9; Ndar 25:6Rĩrĩa Ezara aahooyaga akiumbũraga mehia na akĩrĩraga, o na akĩĩgũithagia thĩ hau nyũmba-inĩ ya Ngai-rĩ, gĩkundi kĩnene kĩa andũ a Isiraeli, kĩa arũme, na andũ-a-nja, na ciana, gĩkĩũngana gĩkĩmũthiũrũrũkĩria. O nao makĩrĩra marĩ na ruo mũno. 210:2 Ezar 9:2Nake Shekania mũrũ wa Jehieli, ũmwe wa rũciaro rwa Elamu, akĩĩra Ezara atĩrĩ, “Tũkoretwo tũtarĩ ehokeku harĩ Ngai witũ nĩ ũndũ nĩtũhikĩtie andũ-a-nja kuuma ndũrĩrĩ iria itũthiũrũrũkĩirie. No o na kũrĩ ũguo-rĩ, Isiraeli no marĩ na kĩĩrĩgĩrĩro. 3Na rĩrĩ, nĩtũthondeke kĩrĩkanĩro tũrĩ mbere ya Ngai witũ atĩ nĩtũkũingata andũ-a-nja aya othe na ciana ciao, kũringana na mataaro ma mwathi wakwa, o na mataaro ma arĩa metigĩrĩte maathani ma Ngai witũ. Ũndũ ũyũ nĩwĩkwo kũringana na Watho. 4Arahũka; ũhoro ũyũ ũrĩ moko-inĩ maku. Ithuĩ tũrĩ hamwe nawe; nĩ ũndũ ũcio, wĩyũmĩrĩrie ũwĩke.”

510:5 Neh 13:25Nĩ ũndũ ũcio Ezara akĩarahũka, agĩtũma atongoria a athĩnjĩri-Ngai na Alawii, o na andũ othe a Isiraeli mehĩte atĩ nĩmegwĩka ũrĩa kwerĩtwo. Nao makĩĩhĩta. 610:6 Thaam 34:28; Jon 3:7Ningĩ Ezara akiuma hau mbere ya nyũmba ya Ngai, agĩthiĩ kanyũmba ka Jehohanani mũrũ wa Eliashibu. Arĩ kũu ndaigana kũrĩa irio kana kũnyua maaĩ tondũ aathiire o na mbere gũcakaya nĩ ũndũ andũ arĩa maatahĩtwo nĩmagĩte kwĩhokeka.

7Gũgĩcooka gũkĩanĩrĩrwo Juda na Jerusalemu guothe atĩ andũ othe arĩa maatahĩtwo mongane Jerusalemu. 8Mũndũ o wothe ũngĩagire gũkinya Jerusalemu mĩthenya ĩtatũ ĩtanathira kũringana na itua rĩa anene na athuuri, atunywo indo ciake ciothe, nake we mwene aingatwo, ehere kĩũngano-inĩ kĩa andũ arĩa maatahĩtwo.

9Mĩthenya ĩyo ĩtatũ ĩtanathira, arũme othe a Juda na Benjamini makĩũngana Jerusalemu. Naguo mũthenya wa mĩrongo ĩĩrĩ wa mweri wa kenda, andũ othe nĩmaikarĩte thĩ kĩhaaro-inĩ kĩrĩa kĩarĩ mbere ya nyũmba ya Ngai, mathĩnĩkĩte mũno tondũ wa ũndũ ũcio na nĩ ũndũ wa mbura. 10Hĩndĩ ĩyo Ezara ũcio mũthĩnjĩri-Ngai akĩrũgama na igũrũ, akĩmeera atĩrĩ, “Mũkoretwo mũtarĩ ehokeku; nĩmũhikĩtie andũ-a-nja a kũngĩ, mũgakĩongerera mahĩtia ma Isiraeli. 1110:11 Mal 2:10-16; Neh 9:2Rĩu-rĩ, umbũrai mehia manyu kũrĩ Jehova Ngai wa maithe manyu, na mwĩke ũrĩa endaga. Mwĩyamũraniei na andũ arĩa mamũthiũrũrũkĩirie, o na atumia anyu a kũngĩ.”

1210:12 Josh 6:5Kĩũngano gĩothe gĩgĩcookia na mũgambo mũnene atĩrĩ, “Nĩwoiga ũrĩa kwagĩrĩire! No nginya twĩke o ta ũguo woiga. 13No rĩrĩ, andũ aya marĩ haha nĩ aingĩ, na nĩ hĩndĩ ya mbura; nĩ ũndũ ũcio tũtingĩikara nja. Ningĩ ũhoro ũyũ ndũngĩthondekeka na mũthenya ũmwe kana ĩĩrĩ, tondũ nĩtwĩhĩtie mũno ũndũ-inĩ ũyũ. 1410:14 Gũcook 16:18; 2Maũ 29:10Reke anene aitũ marũgamĩrĩre kĩũngano gĩkĩ gĩothe. Ningĩ o mũndũ wothe ũrĩ matũũra-inĩ maitũ ũhikĩtie mũndũ-wa-nja wa kũngĩ nĩetĩkĩrio oke mahinda marĩa matuĩtwo, hamwe na athuuri na atuanĩri ciira a o itũũra, nginya twehererio marakara marĩa mahiũ ma Ngai witũ ũhoro-inĩ ũyũ.” 1510:15 Neh 11:16Andũ arĩa maareganire na ũhoro ũcio no Jonathani mũrũ wa Asaheli, na Jahazeia mũrũ wa Tikiva, hamwe na Meshulamu, na Shabethai ũrĩa Mũlawii.

16Nĩ ũndũ ũcio andũ arĩa maatahĩtwo magĩĩka o ta ũrĩa kwerĩtwo. Nake Ezara ũcio mũthĩnjĩri-Ngai agĩthuura arũme arĩa maarĩ atongoria a nyũmba ciao, o mũndũ ũmwe kuuma o nyũmba, o ũrĩa ciagayanĩtio, nao othe makĩandĩkwo marĩĩtwa mao. Mũthenya wa mbere wa mweri wa ikũmi magĩikara thĩ nĩguo matuĩrie maciira macio, 17na gũgĩkinya mũthenya wa mbere wa mweri wa mbere, makĩrĩkia maciira ma arũme othe arĩa maahikĩtie andũ-a-nja a kũngĩ.

Andũ arĩa Maahĩtĩtie nĩ Kũhikania na Ndũrĩrĩ

1810:18 Atiir 3:6Thĩinĩ wa njiaro cia athĩnjĩri-Ngai, andũ aya nĩo maahikĩtie andũ-a-nja a kũngĩ:

Kuuma njiaro cia Jeshua mũrũ wa Jozadaku na ariũ a ithe nĩ:

Maaseia, na Eliezeri, na Jaribu, na Gedalia. 1910:19 2Ath 10:15; Alaw 5:15(Othe makĩĩranĩra atĩ nĩmegũtigana na atumia ao, na o mũndũ akĩruta ndũrũme kuuma rũũru-inĩ rwake nĩ ũndũ wa iruta rĩa mahĩtia mao.)

2010:20 1Maũ 24:14Kuuma kũrĩ njiaro cia Imeri nĩ:

Hanani na Zebadia.

21Kuuma kũrĩ njiaro cia Harimu nĩ:

Maaseia, na Elija, na Shemaia, na Jehieli, na Uzia.

22Kuuma kũrĩ njiaro cia Pashuri nĩ:

Elioenai, na Maaseia, na Ishumaeli, na Nethaneli, na Jozabadu, na Elasa.

2310:23 Neh 8:7Kuuma kũrĩ Alawii nĩ:

Jozabadu, na Shimei, na Kelaia (na nowe Kelita), na Pethahia, na Juda, na Eliezeri.

24Kuuma kũrĩ aini a nyĩmbo nĩ:

Eliashibu.

Kuuma kũrĩ aikaria a ihingo nĩ:

Shakumu, na Telemu, na Uri.

2510:25 Ezar 2:3Na gatagatĩ-inĩ ga Aisiraeli arĩa angĩ:

Kuuma kũrĩ njiaro cia Paroshu nĩ:

Ramia, na Izia, na Malikija, na Mijamini, na Eleazaru, na Malikija, na Benaia.

2610:26 Ezar 10:2Kuuma kũrĩ njiaro cia Elamu nĩ:

Matania, na Zekaria, na Jehieli, na Abadi, na Jeremothu, na Elija.

27Kuuma kũrĩ njiaro cia Zatu nĩ:

Elioenai, na Eliashibu, na Matania, na Jeremothu, na Zabadi, na Aziza.

28Kuuma kũrĩ njiaro cia Bebai nĩ:

Jehohanani, na Hanania, na Zabai, na Athilai.

29Kuuma kũrĩ njiaro cia Bani nĩ:

Meshulamu, na Maluku, na Adaia, na Jashubu, na Sheali, na Jeremothu.

30Kuuma kũrĩ njiaro cia Pahathu-Moabi nĩ:

Adina, na Kelali, na Benaia, na Maaseia, na Matania, na Bezaleli, na Binui, na Manase.

31Kuuma kũrĩ njiaro cia Harimu nĩ:

Eliezeri, na Ishija, na Malikija, na Shemaia, na Shimeoni, 32na Benjamini, na Maluku, na Shemaria.

33Kuuma kũrĩ njiaro cia Hashumu nĩ:

Matenai, na Matata, na Zabadi, na Elifeleti, na Jeremai, na Manase, na Shimei.

34Kuuma kũrĩ njiaro cia Bani nĩ:

Maadai, na Amuramu, na Ueli, 35na Benaia, na Bedeia, na Keluhi, 36na Vania, na Meremothu, na Eliashibu, 37na Matania, na Matenai, na Jaasu.

38Kuuma kũrĩ njiaro cia Binui nĩ:

Shimei, 39na Shelemia, na Nathani, na Adaia, 40na Makinadebai, na Shashai, na Sharai, 41na Azareli, na Shelemia, na Shemaria, 42na Shalumu, na Amaria, na Jusufu.

43Kuuma kũrĩ njiaro cia Nebo nĩ:

Jeieli, na Matithia, na Zabadi, na Zabina, na Jadai, na Joeli, na Benaia.

44Acio othe nĩmahikĩtie andũ-a-nja a kũngĩ, na amwe ao nĩmaciarĩte ciana na atumia acio.

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Esra 10:1-44

Ìjẹ́wọ́ ẹsẹ̀ àwọn ènìyàn

1Nígbà tí Esra ń gbàdúrà tí ó sì ń jẹ́wọ́, ti ó ń sọkún ti ó sì ń gbárayílẹ̀ níwájú ilé Ọlọ́run, ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ Israẹli ọkùnrin, obìnrin àti àwọn ọmọdé pagbo yí i ká. Àwọn náà ń sọkún kíkorò. 2Nígbà náà ni Ṣekaniah ọmọ Jehieli, ọ̀kan lára ìran Elamu, sọ fún Esra pé, Àwa ti jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Ọlọ́run wa nípa fífẹ́ àwọn obìnrin àjèjì láàrín àwọn ènìyàn tí ó wà yí wa ká. Ṣùgbọ́n síbẹ̀ náà, ìrètí sì wà fún Israẹli 3Ní ṣinṣin yìí, ẹ jẹ́ kí a dá májẹ̀mú níwájú Ọlọ́run wa láti lé àwọn obìnrin yìí àti àwọn ọmọ wọn lọ. Gẹ́gẹ́ bí ìmọ̀ràn Esra olúwa mi àti ti àwọn tí ó bẹ̀rù àṣẹ Olúwa Ọlọ́run wa. Ẹ jẹ́ kí a ṣe gẹ́gẹ́ bí òfin. 4Dìde, nítorí, ọ̀rọ̀ tìrẹ ni èyí. Gbogbo wà yóò wá pẹ̀lú rẹ, mú ọkàn le kí o sì ṣe é.

5Nígbà náà ni Esra dìde, ó sì fi àwọn aṣíwájú àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi àti gbogbo Israẹli sí abẹ́ ìbúra, láti ṣe ohun tí wọ́n dá lábàá. Wọ́n sì búra. 6Nígbà náà ni Esra padà sẹ́yìn kúrò níwájú ilé Ọlọ́run, ó sì lọ sí iyàrá Jehohanani ọmọ Eliaṣibu. Nígbà tí ó wà níbẹ̀, kò jẹ oúnjẹ bẹ́ẹ̀ ni kò sì mu omi, nítorí ó sì ń káàánú fún àìṣòótọ́ àwọn ìgbèkùn.

7Ìkéde kan jáde lọ jákèjádò Juda àti Jerusalẹmu fún gbogbo àwọn ìgbèkùn láti péjọ sí Jerusalẹmu. 8Ẹnikẹ́ni tí ó ba kọ̀ láti jáde wá láàrín ọjọ́ mẹ́ta yóò pàdánù ohun ìní rẹ̀ ní ìbámu pẹ̀lú ìpinnu àwọn ìjòyè àti àwọn àgbàgbà, àti pé a ó lé òun fúnrarẹ̀ jáde kúrò láàrín ìpéjọpọ̀ àwọn ìgbèkùn.

9Láàrín ọjọ́ mẹ́ta náà, gbogbo àwọn ọkùnrin Juda àti Benjamini tí péjọ sí Jerusalẹmu. Ní ogúnjọ́ oṣù kẹsànán, gbogbo àwọn ènìyàn jókòó sí ìta gbangba iwájú ilé Ọlọ́run, wọ́n wà nínú ìbànújẹ́ ńlá nítorí ọ̀ràn yìí, àti nítorí òjò púpọ̀ tó tì rọ̀. 10Nígbà náà ni àlùfáà Esra dìde, ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ti ṣe àìṣòótọ́, ẹ ti fẹ́ obìnrin àjèjì, ẹ ti dá kún ẹ̀bi Israẹli. 11Nísinsin yìí, ẹ jẹ́wọ́ níwájú Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba yín, kí ẹ sì ṣe ìfẹ́ rẹ̀. Ẹ ya ara yín sọ́tọ̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn tí ó yí i yín ká àti láàrín àwọn ìyàwó àjèjì yín.”

12Àpéjọpọ̀ ènìyàn náà sì dáhùn lóhùn rara pé: ohun tí ó sọ dára! A gbọdọ̀ ṣe bí o ti wí. 13Ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ ni ó wà ni ibi yìí síbẹ̀ àkókò òjò ni; àwa kò sì lè dúró ní ìta. Yàtọ̀ sí èyí, a kò le è yanjú ọ̀rọ̀ yìí láàrín ọjọ́ kan tàbí ọjọ́ méjì, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wa pọ̀ jọjọ lórí àwọn nǹkan wọ̀nyí. 14Jẹ́ kí àwọn ìjòyè wa ṣojú fún gbogbo ìjọ ènìyàn, lẹ́yìn náà, jẹ́ kí ẹnìkọ̀ọ̀kan nínú àwọn ìlú wa tí ó ti fẹ́ obìnrin àjèjì wá ní àsìkò tí a yàn, pẹ̀lú àwọn àgbàgbà àti àwọn onídàájọ́ ìlú kọ̀ọ̀kan, títí ìbínú gíga Ọlọ́run wa lórí ọ̀rọ̀ yìí yóò fi kúrò ní orí wa. 15Jonatani ọmọ Asaheli àti Jahseiah ọmọ Tikfa nìkan pẹ̀lú àtìlẹ́yìn Meṣullamu àti Ṣabbetai ará Lefi, ni wọ́n tako àbá yìí.

16Nígbà náà ni àwọn ìgbèkùn ṣe gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe fi ẹnu kò sí. Àlùfáà Esra yan àwọn ọkùnrin tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé, ẹnìkọ̀ọ̀kan láti ìdílé kọ̀ọ̀kan, gbogbo wọn ni a sì mọ̀ pẹ̀lú orúkọ wọn. Ní ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kẹwàá, wọ́n jókòó láti ṣe àyẹ̀wò àwọn ẹjọ́ náà, 17Ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kìn-ín-ní ni wọn parí pẹ̀lú àwọn ènìyàn tí wọ́n fẹ́ àwọn obìnrin àjèjì.

Àwọn tó jẹ̀bi ẹ̀sùn ìgbéyàwó pẹ̀lú àjèjì

18Lára ìran àwọn àlùfáà àwọn wọ̀nyí fẹ́ àwọn obìnrin àjèjì:

Nínú ìran Jeṣua ọmọ Josadaki, àti àwọn arákùnrin rẹ:

Maaseiah, Elieseri, Jaribi àti Gedaliah. 19Gbogbo wọn ni wọ́n ṣe ìpinnu láti lé àwọn ìyàwó wọn lọ, wọ́n sì fi àgbò kan láàrín agbo ẹran lélẹ̀ fún ẹ̀bi wọn gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹ̀ṣẹ̀.

20Nínú ìran Immeri:

Hanani àti Sebadiah.

21Nínú ìran Harimu:

Maaseiah, Elijah, Ṣemaiah, Jehieli àti Ussiah.

22Nínú ìran Paṣuri:

Elioenai, Maaseiah, Iṣmaeli, Netaneli, Josabadi àti Eleasa.

23Lára àwọn ọmọ Lefi:

Josabadi, Ṣimei, Kelaiah (èyí tí í ṣe Kelita), Petahiah, Juda àti Elieseri.

24Nínú àwọn akọrin:

Eliaṣibu.

Nínú àwọn aṣọ́nà:

Ṣallumu, Telemu àti Uri.

25Àti lára àwọn ọmọ Israẹli tókù:

Nínú ìran Paroṣi:

Ramiah, Issiah, Malkiah, Mijamini, Eleasari, Malkiah àti Benaiah.

26Nínú ìran Elamu:

Mattaniah, Sekariah, Jehieli, Abdi, Jerimoti àti Elijah.

27Nínú àwọn ìran Sattu:

Elioenai, Eliaṣibu, Mattaniah, Jerimoti, Sabadi àti Asisa.

28Nínú àwọn ìran Bebai:

Jehohanani, Hananiah, Sabbai àti Atlai.

29Nínú àwọn ìran Bani:

Meṣullamu, Malluki, Adaiah, Jaṣubu, Ṣeali àti Jerimoti.

30Nínú àwọn Pahati-Moabu:

Adma, Kelali, Benaiah, Maaseiah, Mattaniah, Besaleli, Binnui àti Manase.

31Nínú àwọn ìran Harimu:

Elieseri, Iṣiah, Malkiah àti Ṣemaiah, Simeoni, 32Benjamini, Malluki àti Ṣemariah.

33Nínú àwọn ìran Haṣumu:

Mattenai, Mattatta, Sabadi, Elifaleti, Jeremai, Manase àti Ṣimei.

34Nínú àwọn ìran Bani:

Maadai, Amramu, Ueli, 35Benaiah, Bediah, Keluhi 36Faniah, Meremoti, Eliaṣibu, 37Mattaniah, Mattenai àti Jaasu.

38Àti Bani, àti Binnui:

Ṣimei, 39Ṣelemiah, Natani, Adaiah, 40Maknadebai, Sasai, Ṣarai, 41Asareeli, Ṣelemiah, Ṣemariah, 42Ṣallumu, Amariah àti Josẹfu.

43Nínú àwọn ìran Nebo:

Jeieli, Mattitiah, Sabadi, Sebina, Jaddai, Joeli àti Benaiah.

44Gbogbo àwọn wọ̀nyí ló fẹ́ obìnrin àjèjì, àwọn mìíràn nínú wọn sì bi ọmọ ní ipasẹ̀ àwọn ìyàwó wọ̀nyí.