何西阿書 13 – CCBT & YCB

Chinese Contemporary Bible (Traditional)

何西阿書 13:1-16

對以色列的最後審判

1以法蓮支派在以色列地位崇高,

他們一開口,人都恐懼顫抖。

但他們卻祭拜巴力,自招滅亡。

2如今他們作惡日甚,

憑藉自己的聰明用銀子鑄造神像,

但這不過是匠人之作。

人們議論他們說:

「那些獻祭的人竟親吻牛犢偶像!」

3他們像晨霧,如轉瞬即逝的朝露,

像麥場上飛旋而去的糠秕,

又像窗口冒出的輕煙。

4耶和華說:

「自從你們離開埃及以來,

我就是你們的上帝耶和華。

除我以外,你們不可有別的神明;

在我以外,你們也沒有別的救主。

5我曾在乾旱的曠野照顧你們,

6但你們吃得飽足以後,

就心高氣傲,忘記了我。

7因此,我要像獅子攻擊你們,

如豹子潛伏在路旁;

8我要像一頭失了幼崽的母熊衝向你們,

撕裂你們的胸膛;

我要像母獅吞噬你們,

像兇猛的野獸撕碎你們。

9以色列啊,你要滅亡了,

因為你抵擋我,抵擋你的幫助者。

10你曾求我為你設立君王和首領,

現在拯救你的君王在哪裡呢?

在各城管理你的首領在哪裡呢?

11我在憤怒中賜給你君王,

也在憤怒中廢黜他們。

12以法蓮的過犯已被記錄在冊,

他的罪惡已被儲存入庫。

13臨產的陣痛要臨到他,

但他是毫無智慧的孩子,

分娩之時卻不離開母腹。

14我要把他們從陰間的權勢下贖回嗎?

我要救他們脫離死亡嗎?

死亡啊,你去降災給他們吧!

陰間啊,你去毀滅他們吧!

我不會再憐憫他們。

15儘管以法蓮在眾弟兄中最強盛,

但炙熱的東風——耶和華的風要從沙漠颳來,

使清泉枯竭,水井乾涸。

他儲藏的一切珍寶都要被擄去。

16撒瑪利亞人背叛了他們的上帝,

要擔當自己的罪過。

他們將喪身刀下,

他們的孩子要被摔死,

孕婦要被剖腹。」

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Hosea 13:1-16

Ìbínú Olúwa sí Israẹli

1Nígbà ti Efraimu bá ń sọ̀rọ̀, àwọn ènìyàn máa ń wárìrì,

a gbé e ga ní Israẹli

ṣùgbọ́n ó jẹ̀bi ẹ̀sùn pé ó ń sin òrìṣà Baali, ó sì kú.

2Báyìí, wọ́n ń dá ẹ̀ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀

wọn fi fàdákà ṣe ère òrìṣà fúnrawọn

ère tí a fi ọgbọ́n dá àrà sí

gbogbo wọn jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ oníṣọ̀nà

Wọn ń sọ nípa àwọn ènìyàn

wọ̀nyí. Pé, Jẹ́ kí àwọn

“Ènìyàn tí ń rú ẹbọ fi ẹnu

ko àwọn ẹgbọrọ màlúù ni ẹnu.”

3Nítorí náà wọn yóò dàbí ìkùùkuu òwúrọ̀,

bí ìrì òwúrọ̀ kùtùkùtù tó máa ń parẹ́,

bí i èèpo ìyẹ̀fun tí afẹ́fẹ́ gbé láti ibi ìpakà

bí èéfín tó rú jáde gba ojú fèrèsé.

4“Ṣùgbọ́n Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ̀,

ẹni tó mú ọ jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá.

Ìwọ̀ kì yóò sì mọ ọlọ́run mìíràn àfi èmi

kò sí olùgbàlà mìíràn lẹ́yìn mi

5Mo ṣe ìtọ́jú rẹ ní aginjù

ní ilẹ̀ tí ó gbẹ tí kò ní omi

6Wọn ni ìtẹ́lọ́rùn nígbà tí mo fún wọn ní oúnjẹ

Nígbà tí wọ́n ní ìtẹ́lọ́rùn tan wọ́n di agbéraga

Nígbà náà ni wọ́n sì gbàgbé mi.

7Nítorí náà, Èmi yóò dìde sí wọn bí i kìnnìún

Èmi yóò fi ara pamọ́ dè wọ́n lọ́nà bí i ẹkùn.

8Beari igbó tí a já ọmọ rẹ̀ gbà

Èmi yóò bá wọn jà bí?

Èmi yóò sì fà wọ́n ya

bí ìgbà tí ẹkùn bá fa ara wọn ya

bi ẹranko búburú ni èmi yóò fa wọn ya.

9“A ti pa ọ́ run, ìwọ Israẹli

nítorí pé ìwọ lòdì sí mi, ìwọ lòdì sí olùrànlọ́wọ́ rẹ.

10Níbo ni ọba rẹ gbé wà nísinsin yìí kí ó bá à le gbà ọ là?

Níbo ni àwọn olórí ìlú yín wà,

àwọn tí ẹ sọ pé,

‘Fún wa ní ọba àti ọmọ-aládé’?

11Nítorí èyí nínú ìbínú mi ni mo fún un yín ní ọba,

Nínú ìbínú gbígbóná mi, mo sì mú un kúrò.

12Ẹ̀bi Efraimu ni a tí ko jọ

gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ wà nínú àkọsílẹ̀

13Ìrora bí obìnrin tó fẹ́ bímọ ti dé bá a

Ṣùgbọ́n ó jẹ́ ọmọ tí kò lọ́gbọ́n

Nígbà tí àsìkò tó,

ó kọ̀ láti jáde síta láti inú.

14“Èmi yóò rà wọ́n padà kúrò lọ́wọ́ agbára isà òkú.

Èmi yóò rà wọ́n padà lọ́wọ́ ikú

Ikú, àjàkálẹ̀-ààrùn rẹ dà?

Isà òkú, ìparun rẹ dà?

“Èmi kò ní ṣàánú mọ́.

15Bí ó tilẹ̀ gbilẹ̀ láàrín àwọn arákùnrin rẹ̀

afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn láti ọ̀dọ̀ Olúwa yóò wá,

Yóò fẹ́ wá láti inú aginjù

orísun omi rẹ̀ yóò gbẹ

kànga rẹ̀ yóò gbẹ

pẹ̀lú olè yóò fọ́ ilé ẹrù

àti gbogbo ilé ìṣúra rẹ̀

16Ará Samaria gbọdọ̀ ru ẹ̀bi wọn,

nítorí pé wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ sí Ọlọ́run wọn.

Wọn ó ti ipa idà ṣubú;

a ó fọ́ àwọn ọmọ wọn mọ́lẹ̀,

A ó sì la àwọn aboyún wọn nínú.”