第 9 篇
称颂上帝的公义
大卫的诗,交给乐长,调用“慕拉辨”9:0 “慕拉辨”希伯来文的意思是“丧子”。。
1耶和华啊,
我要全心全意地赞美你,
传扬你一切奇妙的作为。
2我要因你欢喜快乐,
至高者啊,我要歌颂你的名。
3我的仇敌必在你面前败退,
倒地身亡。
4你坐在宝座上按公义审判,
你为我主持公道。
5你斥责列国,消灭恶人,
永永远远抹去他们的名字。
6仇敌永远灭亡了,
你把他们的城池连根拔起,
无人再记得他们。
7耶和华永远掌权,
祂已设立施行审判的宝座。
8祂要以公义审判世界,
在万民中伸张正义。
9耶和华是受欺压之人的避难所,
是他们患难之时的避风港。
10耶和华啊,
凡认识你名的人都必信靠你,
因为你从来不丢弃寻求你的人。
11要歌颂住在锡安的耶和华,
在列邦传扬祂的作为。
12祂追讨血债,顾念受害者,
不忘倾听受苦者的呼求。
13耶和华啊,
看看仇敌对我的迫害!
求你怜悯我,
救我离开死亡之门,
14我好在锡安的城门口称颂你,
因你的拯救而欢乐。
15列邦挖了陷阱却自陷其中,
设下网罗却缠住自己的脚。
16耶和华彰显了自己的公义,
使恶人自食其果。(细拉)
17恶人必下阴间,这是所有忘记上帝之人的结局。
18贫乏人不会永远被遗忘,
受苦人的希望也不会一直落空。
19耶和华啊,求你起来,
别让人向你夸胜,
愿你审判列邦。
20耶和华啊,
求你使列邦恐惧战抖,
让他们明白自己不过是人。(细拉)
Saamu 9
Fún adarí orin. Ní ti ohun orin “Ní ti ikú ọmọ.” Saamu ti Dafidi.
1Èmi ó yìn ọ́, Olúwa, pẹ̀lú gbogbo ọkàn mi;
Èmi ó sọ ti ìyanu rẹ gbogbo.
2Inú mi yóò dùn, èmi yóò sì yọ̀ nínú rẹ;
Èmi ó kọrin ìyìn sí orúkọ rẹ, Ìwọ Ọ̀gá-Ògo jùlọ.
3Àwọn ọ̀tá mi pẹ̀yìndà;
Wọ́n kọsẹ̀ wọn sì ṣègbé níwájú rẹ.
4Nítorí ìwọ ti di òtítọ́ àti ọ̀ràn mi mú;
ìwọ ti jókòó lórí ìtẹ́ rẹ, láti ṣe ìdájọ́ òdodo.
5Ìwọ ti bá orílẹ̀-èdè wí, Ìwọ sì ti pa ẹni búburú run;
Ìwọ ti yọ orúkọ wọn kúrò láé àti láéláé.
6Ìparun àìlópin ti borí àwọn ọ̀tá,
Ìwọ ti fa àwọn ìlú wọn tu;
àní ìrántí wọn sì ti ṣègbé.
7Olúwa jẹ ọba títí láé;
ó ti gbé ìtẹ́ rẹ̀ kalẹ̀ fún ìdájọ́.
89.8: Ap 17.31.Òun yóò sì ṣe ìdájọ́ ayé ní òdodo;
yóò ṣe àkóso ènìyàn pẹ̀lú òdodo.
9Olúwa ni ààbò fún àwọn tí a ni lára,
ibi ìsádi ní àkókò ìpọ́njú.
10Àwọn tí ó mọ orúkọ rẹ yóò gbẹ́kẹ̀lé ọ,
nítorí, Olúwa, kò kọ àwọn tó ń wá a sílẹ̀.
11Kọ orin ìyìn sí Olúwa, tí o ń jẹ ọba ní Sioni;
kéde láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ohun tí ó ṣe.
12Nítorí ẹni tí ó ń gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ rántí;
òun kò kọ ẹkún àwọn tí a pọ́n lójú.
13Olúwa, wo bí àwọn ọ̀tá ṣe ń ṣe inúnibíni sí mi!
Ṣàánú, kí o sì gbé mí sókè kúrò ní ẹnu-ọ̀nà ikú,
14Kí èmi kí ó lè sọ ti ìyìn rẹ
ni ẹnu-ọ̀nà àwọn ọmọbìnrin Sioni
àti láti máa yọ̀ nínú ìgbàlà rẹ.
15Àwọn orílẹ̀-èdè ti jì sí kòtò tí wọn ti gbẹ́;
ẹsẹ̀ wọn ni àwọ̀n tí wọ́n dẹ sílẹ̀ kọ́.
16A mọ Olúwa nípa òdodo rẹ̀;
àwọn ènìyàn búburú ni a dẹ́kun mú nípa iṣẹ́ ọwọ́ wọn.
17Àwọn ènìyàn búburú ni a ó dà sí isà òkú,
àti gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó gbàgbé Ọlọ́run.
18Ṣùgbọ́n àwọn aláìní ni a kò ní gbàgbé láéláé,
ìrètí àwọn ti ó tálákà ni a kì yóò gbàgbé láéláé.
19Dìde, Olúwa, má ṣe jẹ́ kí ènìyàn borí;
Jẹ́ kí a ṣe ìdájọ́ àwọn orílẹ̀-èdè ni iwájú rẹ.
20Lù wọ́n pẹ̀lú ìpayà, Olúwa;
jẹ́ kí àwọn orílẹ̀-èdè mọ̀ pé ènìyàn lásán ni wọ́n. Sela.