Nnwom 126 – AKCB & YCB

Akuapem Twi Contemporary Bible

Nnwom 126:1-6

Dwom 126

Ɔsoroforo dwom.

1Bere a Awurade de Sion fi nnommum san bae no,

yɛyɛɛ sɛ wɔn a wɔsosoo adae.

2Ɔserew hyɛɛ yɛn anom ma,

anigye nnwom hyɛɛ yɛn tɛkrɛma so ma.

Na wɔkaa wɔ amanaman no mu se,

Awurade ayɛ nneɛma akɛse ama wɔn.”

3Awurade ayɛ nneɛma akɛse ama yɛn,

na anigye ahyɛ yɛn ma.

4Awurade, san fa yɛn siade ma yɛn,

te sɛ nsuwansuwa a ɛwɔ Negeb no.

5Wɔn a wodua no nusu mu no

de anigye nnwom betwa.

6Wɔn a wɔde osu fi adi

so aba a wɔrekodua no,

de anigye nnwom bɛsan aba

a wɔsoso nnɔbae afiafi.

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 126:1-6

Saamu 126

Orin fún ìgòkè.

1Nígbà tí Olúwa mú ìkólọ Sioni padà,

àwa dàbí ẹni tí ó ń lá àlá.

2Nígbà náà ni ẹnu wa kún fún ẹ̀rín,

àti ahọ́n wa kọ orin;

nígbà náà ni wọ́n wí nínú àwọn kèfèrí pé,

Olúwa ṣe ohun ńlá fún wọn.

3Olúwa ṣe ohun ńlá fún wa;

nítorí náà àwa ń yọ̀.

4Olúwa mú ìkólọ wa padà,

bí ìṣàn omi ní gúúsù.

5Àwọn tí ń fi omijé fún irúgbìn

yóò fi ayọ̀ ka.

6Ẹni tí ń fi ẹkún rìn lọ,

tí ó sì gbé irúgbìn lọ́wọ́,

lóòtítọ́, yóò fi ayọ̀ padà wá,

yóò sì ru ìtí rẹ̀.