Saamu 128 – YCB & NVI-PT

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 128:1-6

Saamu 128

Orin fún ìgòkè.

1Ìbùkún ni fún gbogbo ẹni tí ó bẹ̀rù Olúwa:

tí ó sì ń rìn ní ọ̀nà rẹ̀.

2Nítorí tí ìwọ yóò jẹ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ

ìbùkún ni fún ọ; yóò sì dára fún ọ.

3Obìnrin rẹ yóò dàbí àjàrà rere

eléso púpọ̀ ní àárín ilé rẹ;

àwọn ọmọ rẹ yóò dàbí igi olifi tí ó yí tábìlì rẹ ká.

4Kíyèsi i pé, bẹ́ẹ̀ ni a ó bùsi i fún ọkùnrin náà,

tí ó bẹ̀rù Olúwa.

5Olúwa kí ó bùsi i fún ọ láti Sioni wá,

kí ìwọ kí ó sì máa rí ìre

Jerusalẹmu ní ọjọ́ ayé rẹ gbogbo.

6Bẹ́ẹ̀ ni kí ìwọ kí ó sì máa rí àti ọmọdọ́mọ rẹ.

Láti àlàáfíà lára Israẹli.

Nova Versão Internacional

Salmos 128:1-6

Salmo 128

Cântico de Peregrinação.

1Como é feliz quem teme o Senhor,

quem anda em seus caminhos!

2Você comerá do fruto do seu trabalho

e será feliz e próspero.

3Sua mulher será como videira frutífera

em sua casa;

seus filhos serão como brotos de oliveira

ao redor da sua mesa.

4Assim será abençoado

o homem que teme o Senhor!

5Que o Senhor o abençoe desde Sião,

para que você veja a prosperidade de Jerusalém

todos os dias da sua vida

6e veja os filhos dos seus filhos.

Haja paz em Israel!