Saamu 126
Orin fún ìgòkè.
1Nígbà tí Olúwa mú ìkólọ Sioni padà,
àwa dàbí ẹni tí ó ń lá àlá.
2Nígbà náà ni ẹnu wa kún fún ẹ̀rín,
àti ahọ́n wa kọ orin;
nígbà náà ni wọ́n wí nínú àwọn kèfèrí pé,
Olúwa ṣe ohun ńlá fún wọn.
3Olúwa ṣe ohun ńlá fún wa;
nítorí náà àwa ń yọ̀.
4Olúwa mú ìkólọ wa padà,
bí ìṣàn omi ní gúúsù.
5Àwọn tí ń fi omijé fún irúgbìn
yóò fi ayọ̀ ka.
6Ẹni tí ń fi ẹkún rìn lọ,
tí ó sì gbé irúgbìn lọ́wọ́,
lóòtítọ́, yóò fi ayọ̀ padà wá,
yóò sì ru ìtí rẹ̀.
Salmo 126
Cântico de Peregrinação.
1Quando o Senhor trouxe os cativos
de volta a Sião126.1 Ou trouxe restauração a Sião, foi como um sonho.
2Então a nossa boca encheu-se de riso
e a nossa língua de cantos de alegria.
Até nas outras nações se dizia:
“O Senhor fez coisas grandiosas por este povo”.
3Sim, coisas grandiosas fez o Senhor por nós,
por isso estamos alegres.
4Senhor, restaura-nos126.4 Ou traze nossos cativos de volta,
assim como enches o leito dos ribeiros no deserto126.4 Ou Neguebe.
5Aqueles que semeiam com lágrimas,
com cantos de alegria colherão.
6Aquele que sai chorando
enquanto lança a semente,
voltará com cantos de alegria,
trazendo os seus feixes.