Matiu 2 – YCB & CARST

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Matiu 2:1-23

Ìbẹ̀wò àwọn amòye

12.1: Lk 2.4-7; 1.5.Lẹ́yìn ìgbà tí a bí Jesu ní Bẹtilẹhẹmu ti Judea, ni àkókò ọba Herodu, àwọn amòye ti ìlà-oòrùn wá sí Jerusalẹmu. 22.2: Jr 23.5; Sk 9.9; Mk 15.2; Jh 1.49; Nu 24.17.Wọ́n si béèrè pé, “Níbo ni ẹni náà tí a bí tí í ṣe ọba àwọn Júù wà? Àwa ti rí ìràwọ̀ rẹ̀ ní ìlà-oòrùn, a sì wá láti foríbalẹ̀ fún un.”

3Nígbà tí ọba Herodu sì gbọ́ èyí, ìdààmú bá a àti gbogbo àwọn ara Jerusalẹmu pẹ̀lú rẹ̀. 4Nígbà tí ó sì pe àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin jọ, ó bi wọ́n léèrè níbi ti a ó gbé bí Kristi? 52.5: Jh 7.42.Wọ́n sì wí pé, “Ní Bẹtilẹhẹmu ti Judea, èyí ni ohun tí wòlíì ti kọ ìwé rẹ̀ pé,

62.6: Mik 5.2.“ ‘Ṣùgbọ́n ìwọ Bẹtilẹhẹmu, ní ilẹ̀ Judea,

ìwọ kò kéré jù láàrín àwọn ọmọ-aládé Juda;

nítorí láti inú rẹ ni Baálẹ̀ kan yóò ti jáde,

ẹni ti yóò ṣe ìtọ́jú Israẹli, àwọn ènìyàn mi.’ ”

7Nígbà náà ni Herodu ọba pe àwọn amòye náà sí ìkọ̀kọ̀, ó sì wádìí ni ọwọ́ wọn, àkókò náà gan an tí wọ́n kọ́kọ́ rí ìràwọ̀. 8Ó sì rán wọn lọ sí Bẹtilẹhẹmu, ó sì wí pé, “Ẹ lọ ṣe ìwádìí fínní fínní ní ti ọmọ náà tí a bí. Lẹ́yìn tí ẹ bá sì rí i, ẹ padà wá sọ fún mi, kí èmi náà le lọ foríbalẹ̀ fún un.”

9Nígbà tí wọ́n sì gbọ́ ọ̀rọ̀ ọba, wọ́n mú ọ̀nà wọn pọ̀n, sì wò ó, ìràwọ̀ tí wọ́n ti rí láti ìhà ìlà-oòrùn wá, ó ṣáájú wọn, títí tí ó fi dúró lókè ibi tí ọmọ náà gbé wà. 10Nígbà tí wọ́n sì rí ìràwọ̀ náà, ayọ̀ kún ọkàn wọn. 112.11: Mt 1.18; 12.46.Bí wọ́n tí wọ inú ilé náà, wọn rí ọmọ ọwọ́ náà pẹ̀lú Maria ìyá rẹ̀, wọ́n wólẹ̀, wọ́n foríbalẹ̀ fún un. Nígbà náà ni wọ́n tú ìṣúra wọn, wọ́n sì ta Jesu lọ́rẹ: wúrà, tùràrí àti òjìá. 122.12: Mt 2.22; Ap 10.22; Hb 11.7.Nítorí pé Ọlọ́run ti kìlọ̀ fún wọn ní ojú àlá pé kí wọ́n má ṣe padà tọ Herodu lọ mọ́, wọ́n gba ọ̀nà mìíràn lọ sí ìlú wọn.

A gbé Jesu sálọ sì Ejibiti

13Nígbà tí wọn ti lọ, angẹli Olúwa fi ara hàn Josẹfu ní ojú àlá pé, “Dìde, gbé ọmọ ọwọ́ náà àti ìyá rẹ̀, kí ó sì sálọ sí Ejibiti. Dúró níbẹ̀ títí tí èmi yóò fi sọ fún ọ, nítorí Herodu yóò wá ọ̀nà láti pa ọmọ ọwọ́ náà.”

14Nígbà náà ni ó sì dìde, ó mú ọmọ ọwọ́ náà àti ìyá rẹ̀ ní òru, ó sì lọ sí Ejibiti, 152.15: Ho 11.1.ó sì wà níbẹ̀ títí tí Herodu fi kú. Èyí jẹ́ ìmúṣẹ àsọtẹ́lẹ̀ ohun tí Olúwa sọ láti ẹnu wòlíì pé, “Mo pe ọmọ mi jáde láti Ejibiti wá.”

16Nígbà tí Herodu rí í pé àwọn amòye náà ti tan òun jẹ, ó bínú gidigidi, ó sì pàṣẹ kí a pa gbogbo àwọn ọmọkùnrin tí ó wà ní Bẹtilẹhẹmu àti ní ẹkùn rẹ̀ láti àwọn ọmọ ọdún méjì sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bi àkókò tí ó ti fi ẹ̀sọ̀ ẹ̀sọ̀ béèrè lọ́wọ́ àwọn amòye náà. 17Nígbà náà ni èyí tí a ti sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu wòlíì Jeremiah wá ṣẹ pé:

182.18: Jr 31.15.“A gbọ́ ohùn kan ní Rama,

ohùn réré ẹkún àti ọ̀fọ̀ ńlá,

Rakeli ń sọkún àwọn ọmọ rẹ̀.

Ó kọ̀ láti gbìpẹ̀

nítorí àwọn ọmọ rẹ̀ kò sí mọ́.”

Ìpadà sí Nasareti

192.19: Mt 1.20; 2.13.Lẹ́yìn ikú Herodu, angẹli Olúwa fi ara hàn Josẹfu lójú àlá ní Ejibiti 20Ó sì wí fún un pé, “Dìde gbé ọmọ ọwọ́ náà àti ìyá rẹ̀ padà sí ilẹ̀ Israẹli, nítorí àwọn tí ń wá ẹ̀mí ọmọ ọwọ́ náà láti pa ti kú.”

21Nítorí náà, o sì dìde, ó gbé ọmọ ọwọ́ náà àti ìyá rẹ̀ ó sì wá sí ilẹ̀ Israẹli. 22Ṣùgbọ́n nígbà tí ó gbọ́ pé Akelausi ni ó ń jẹ ọba ní Judea ní ipò Herodu baba rẹ̀, ó bẹ̀rù láti lọ sí ì bẹ̀. Nítorí tí Ọlọ́run ti kìlọ̀ fún un ní ojú àlá, ó yí padà, ó sì gba ẹkùn Galili lọ, 232.23: Lk 1.26; Mk 1.24.ó sì lọ í gbé ní ìlú tí a pè ní Nasareti. Nígbà náà ni èyí tí a sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu àwọn wòlíì wá sí ìmúṣẹ: “A ó pè é ní ará Nasareti.”

Священное Писание (Восточный перевод), версия для Таджикистана

Матто 2:1-23

Восточные мудрецы

1Исо родился в иудейском городе Вифлееме во времена правления царя Ирода2:1 Это Ирод Великий, который правил Иудеей, Сомарией и Галилеей с 37 по 4 гг. до н. э.. После рождения Исо в Иерусалим пришли мудрецы с востока2:1 Скорее всего, упоминаемые здесь мудрецы были зороастрийскими жрецами из Персии, которые, основываясь на собственных или же иудейских религиозных источниках, искали грядущего Царя-Спасителя..

Они спрашивали людей:

2– Где новорождённый Царь иудеев? Мы видели Его звезду на востоке2:2 Или: «Мы видели, как взошла Его звезда». См. Чис. 24:17. и пришли поклониться Ему.

3Услышав об этом, царь Ирод встревожился, а с ним и весь Иерусалим. 4Царь созвал к себе всех главных священнослужителей и учителей Таврота и спросил их, где должен родиться обещанный Масех.

5– В иудейском Вифлееме, – ответили ему, – потому что так написано у пророка:

6«И ты, Вифлеем в земле Иудеи,

ты вовсе не наименьший среди главных городов Иудеи,

потому что из тебя произойдёт Правитель,

Который будет пасти народ Мой, Исроил!»2:6 Мих. 5:2.

7Тогда Ирод тайно пригласил к себе мудрецов и выведал у них точное время появления звезды. 8Он послал их в Вифлеем с наказом:

– Идите и тщательно всё разузнайте о младенце. Когда вы Его найдёте, известите и меня, чтобы я смог пойти и поклониться Ему.

9Выслушав наказ царя, мудрецы отправились в путь. Звезда, которую они видели на востоке2:9 Или: «Звезда, восход которой они видели»., шла впереди них, пока наконец не остановилась над местом, где был младенец. 10Увидев звезду, мудрецы очень сильно обрадовались. 11Когда они вошли в дом и увидели младенца и Его мать Марьям, они, павши, поклонились Ему и, открыв свои сокровища, поднесли Ему подарки: золото, ладан2:11 Ладан – ценная ароматическая смола растений, произрастающих в Аравии и Северной Африке. См. пояснительный словарь. и смирну2:11 Смирна (мирра) – приятно пахнущая смола растущего в Аравии растения.. 12Ночью во сне они были предупреждены о том, что им нельзя возвращаться к Ироду, и вернулись в свою страну другим путём.

Бегство в Египет

13Когда мудрецы ушли, Юсуфу во сне явился ангел от Вечного и сказал:

– Вставай, возьми младенца и Его мать и беги с ними в Египет. Оставайтесь там, пока я не скажу, потому что Ирод собирается найти младенца и убить Его.

14Юсуф взял младенца с Его матерью, и ночью они ушли в Египет. 15Там они оставались до тех пор, пока Ирод не умер. Так исполнились слова, которые Вечный сказал через пророка: «Из Египта призвал Я Сына Моего»2:15 Ос. 11:1. То, что Вечный говорит через пророка Осию об исроильском народе, Матто относит к Исо Масеху, тем самым показывая, что в Нём нашли своё отражение все ожидания и чаяния Вечного, которые Он возлагал на исроильский народ..

16Когда Ирод понял, что мудрецы его обманули, он пришёл в ярость и приказал убить в Вифлееме и его окрестностях всех мальчиков в возрасте до двух лет. Время рождения младенца он определил со слов мудрецов. 17Таким образом исполнилось предсказанное через пророка Иеремию:

18«Голос слышен в Раме,

вопль и горькое рыдание, –

это Рахиля плачет о детях своих

и не находит утешения,

потому что их больше нет!»2:18 Иер. 31:15.

Возвращение в Назарет

19После смерти Ирода Юсуфу в Египте явился во сне ангел от Вечного.

20– Вставай, – сказал он, – возьми младенца и Его мать и возвращайтесь в Исроил. Тех, кто хотел убить мальчика, уже нет в живых.

21Юсуф взял младенца и Его мать, и они отправились в землю Исроила. 22Когда Юсуф узнал, что в Иудее вместо Ирода царствует его сын Архелай, он побоялся возвращаться, но, получив во сне ещё одно указание, пошёл в Галилею 23и поселился там в городе Назарете. Так исполнились слова пророков, что Масеха будут называть назарянином2:23 То есть будет в пренебрежении (см. Заб. 21:7; Ис. 53:3; Ин. 1:46). Но здесь возможна и связь с еврейским словом нецер («ветвь») (см. Ис. 11:1). Однако некоторые комментаторы не исключают связи и со словом «назорей» (см. Чис. 6:1-21; Суд. 13:5)..