Àṣọtẹ́lẹ̀ nípa Moabu
148.1-47: Isa 15.1–16.14; 25.10-12; El 25.8-11; Am 2.1-3; Sf 2.8-11.Nípa Moabu.
Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí:
“Ègbé ni fún Nebo nítorí a ó parun.
A dójútì Kiriataimu, a sì mú un,
ojú yóò ti alágbára, a ó sì fọ́nká.
2Moabu kò ní ní ìyìn mọ́,
ní Heṣboni ni wọn ó pète ìparun rẹ̀,
‘Wá, kí a pa orílẹ̀-èdè náà run.’
Àti ẹ̀yin òmùgọ̀ ọkùnrin pàápàá ni a ó pa lẹ́nu mọ́,
a ó fi idà lé e yín.
3Gbọ́ igbe ní Horonaimu,
igbe ìrora àti ìparun ńlá.
4Moabu yóò di wíwó palẹ̀;
àwọn ọmọdé rẹ̀ yóò kígbe síta.
5Wọ́n gòkè lọ sí Luhiti,
wọ́n ń sọkún kíkorò bí wọ́n ti ń lọ;
ní ojú ọ̀nà sí Horonaimu
igbe ìrora ìparun ni à ń gbọ́ lọ.
6Sá! Àsálà fún ẹ̀mí yín;
kí ẹ sì dàbí aláìní ní aginjù.
7Níwọ́n ìgbà tí o gbẹ́kẹ̀lé agbára àti ọrọ̀ rẹ,
a ó kó ìwọ náà ní ìgbèkùn,
Kemoṣi náà yóò lọ sí ilẹ̀ ìgbèkùn
pẹ̀lú àlùfáà àti àwọn aláṣẹ rẹ̀.
8Gbogbo ìlú rẹ ni apanirun yóò dojúkọ,
ìlú kan kò sì ní le là.
Àfonífojì yóò di ahoro
àti ilẹ̀ títẹ́ ni a ó run,
nítorí tí Olúwa ti sọ̀rọ̀.
9Fi iyọ̀ sí Moabu,
nítorí yóò ṣègbé,
àwọn ìlú rẹ yóò sì di ahoro
láìsí ẹni tí yóò gbé inú rẹ̀.
10“Ìfibú ni fún ẹni tí ó fi ìmẹ́lẹ́ ṣe iṣẹ́ Olúwa,
ìfibú ni fún ẹni tí ó pa idà mọ́ fún ìtàjẹ̀ sílẹ̀.
11“Moabu ti wà ní ìsinmi láti ìgbà èwe rẹ̀ wá
bí i ọtí wáìnì lórí gẹ̀dẹ̀gẹ́dẹ̀ rẹ̀,
tí a kò dà láti ìgò kan sí èkejì
kò tí ì lọ sí ilẹ̀ ìgbèkùn rí.
Ó dùn lẹ́nu bí ó ti yẹ,
òórùn rẹ̀ kò yí padà.
12Ṣùgbọ́n ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí,
“nígbà tí n ó rán àwọn tí ó n da ọtí láti inú àwọn ìgò
tí wọ́n ó sì dà á síta;
wọn ó sọ àwọn ìgò rẹ̀ di òfo,
wọn ó sì fọ́ àwọn ife rẹ̀.
13Nígbà náà Moabu yóò sì tú u nítorí Kemoṣi,
bí ojú ti í ti ilé Israẹli
nígbà tí ó gbẹ́kẹ̀lé Beteli.
14“Báwo ni o ṣe lè sọ pé, ‘Ajagun ni wá,
alágbára ní ogun jíjà’?
15A ó pa Moabu run, a ó sì gba àwọn ìlú rẹ̀;
a ó sì dúńbú àwọn arẹwà ọkùnrin rẹ̀,”
ni ọba wí, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
16“Ìṣubú Moabu súnmọ́;
ìpọ́njú yóò dé kánkán.
17Ẹ dárò fún, gbogbo ẹ̀yin tí ó yí i ká
gbogbo ẹ̀yin tí ẹ mọ bí ó ti ní òkìkí tó.
Ẹ sọ pé, ‘Báwo ni ọ̀pá agbára rẹ
títóbi tí ó sì lógo ṣe fọ́!’
18“Sọ̀kalẹ̀ níbi ògo rẹ,
kí o sì jókòó ní ilẹ̀ gbígbẹ,
ẹ̀yin olùgbé ọmọbìnrin Diboni,
nítorí tí ẹni tí ó pa Moabu run
yóò dojúkọ ọ́
yóò sì pa àwọn ìlú olódi rẹ run.
19Dúró lẹ́bàá ọ̀nà kí o sì wòran,
ìwọ tí ń gbé ní Aroeri.
Bí ọkùnrin tí ó sálọ àti obìnrin tí ó ń sá àsálà
‘Kí ni ohun tí ó ṣẹlẹ̀?’
20Ojú ti Moabu nítorí tí a wó o lulẹ̀.
Ẹ hu, kí ẹ sì kígbe!
Ẹ kéde rẹ̀ ní Arnoni pé,
a pa Moabu run.
21Ìdájọ́ ti dé sí àwọn òkè pẹrẹsẹ,
sórí Holoni, Jahisa àti Mefaati,
22sórí Diboni, Nebo àti Beti-Diblataimu,
23sórí Kiriataimu, Beti-Gamu àti Beti-Meoni,
24sórí Kerioti àti Bosra,
sórí gbogbo ìlú Moabu, nítòsí àti ní ọ̀nà jíjìn.
25A gé ìwo Moabu kúrò,
apá rẹ̀ dá,”
ni Olúwa wí.
26“Ẹ jẹ́ kí a mú u mutí
nítorí ó kó ìdọ̀tí bá Olúwa,
jẹ́ kí Moabu lúwẹ̀ẹ́ nínú èébì rẹ̀,
kí ó di ẹni ẹ̀gàn.
27Ǹjẹ́ Israẹli kò di ẹni ẹ̀gàn rẹ?
Ǹjẹ́ a kó o pẹ̀lú àwọn olè
tó bẹ́ẹ̀ tí o ń gbọn orí rẹ̀ pẹ̀lú yẹ̀yẹ́
nígbàkígbà bí a bá sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀?
28Kúrò ní àwọn ìlú rẹ, kí o sì máa gbé láàrín àwọn òkúta,
ẹ̀yin tí ó ti ń gbé inú ìlú Moabu.
Ẹ dàbí i àdàbà tí ó kọ́ ìtẹ́ rẹ̀
sí ẹnu ihò.
29“A ti gbọ́ nípa ìgbéraga Moabu:
àti ìwà mo gbọ́n tan rẹ̀
àti ìgbéraga ọkàn rẹ̀.
30Mo mọ àfojúdi rẹ̀, ṣùgbọ́n òfo ni,” ni Olúwa wí,
“ìfọ́nnu rẹ̀ kò lè ṣe nǹkan kan.
31Nítorí náà, mo pohùnréré ẹkún lórí Moabu
fún àwọn ará Moabu ni mo kígbe lóhùn rara,
mo kẹ́dùn fún àwọn ọkùnrin Kiri-Hareseti.
32Mo sọkún fún ọ bí Jaseri ṣe sọkún
ìwọ àjàrà Sibma.
Ẹ̀ka rẹ tẹ̀ títí dé Òkun,
wọn dé Òkun Jaseri.
Ajẹnirun ti kọlu èso rẹ,
ìkórè èso àjàrà rẹ.
33Ayọ̀ àti ìdùnnú ti kúrò
nínú ọgbà àjàrà àti oko Moabu.
Mo dá ọwọ́ ṣíṣàn ọtí wáìnì dúró lọ́dọ̀ olùfúntí;
kò sí ẹni tí ó ń tẹ̀ wọ́n pẹ̀lú igbe ayọ̀.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé igbe wà,
wọn kì í ṣe igbe ti ayọ̀.
34“Ohùn igbe wọn gòkè
láti Heṣboni dé Eleale àti Jahasi,
láti Soari títí dé Horonaimu àti Eglati-Ṣeliṣi,
nítorí àwọn omi Nimrimu pẹ̀lú yóò gbẹ.
35Ní ti Moabu ni èmi yóò ti fi òpin sí
ẹni tí ó rú ẹbọ ní ibí gíga
àti ẹni tí ń sun tùràrí fún òrìṣà rẹ̀,”
ni Olúwa wí.
36“Nítorí náà ọkàn mi ró fún Moabu bí fèrè,
ọkàn mi ró bí fèrè fún àwọn ọkùnrin Kiri-Hareseti.
Nítorí ìṣúra tí ó kójọ ṣègbé.
37Gbogbo orí ni yóò pá,
gbogbo irùngbọ̀n ni a ó gé kúrò,
gbogbo ọwọ́ ni a sá lọ́gbẹ́,
àti aṣọ ọ̀fọ̀ ní gbogbo ẹ̀gbẹ́.
38Ẹkún ńlá ní yóò wà lórí gbogbo òrùlé Moabu,
àti ní ìta rẹ̀,
nítorí èmi ti fọ́ Moabu
bí a ti ń fọ́ ohun èlò tí kò wu ni,”
ni Olúwa wí.
39“Èéṣe tí ẹ fi fọ́ túútúú,
tí ẹ sì fi ń pohùnréré ẹkún!
Báwo ni Moabu ṣe yí
ẹ̀yìn padà ní ìtìjú!
Moabu ti di ẹni ìtìjú àti ẹ̀gàn àti
ìdààmú sí gbogbo àwọn tí ó yìí ká.”
40Báyìí ni Olúwa wí:
“Wò ó ẹyẹ idì náà ń fò bọ̀ nílẹ̀
ó sì na ìyẹ́ rẹ̀ lórí Moabu.
41Kerioti ni a ó kó lẹ́rú àti ilé agbára ni ó gbà.
Ní ọjọ́ náà ọkàn àwọn akọni Moabu
yóò dàbí ọkàn obìnrin tí ó ń rọbí.
42A ó pa Moabu run gẹ́gẹ́ bí
orílẹ̀-èdè nítorí pé ó gbéraga sí Olúwa.
43Ẹ̀rù àti ọ̀fìn àti okùn dídè
ń dúró dè yín, ẹ̀yin ènìyàn Moabu,”
ní Olúwa wí.
44“Ẹnikẹ́ni tí ó bá sá fún
ẹ̀rù yóò ṣubú sínú ọ̀fìn
ẹnikẹ́ni tí o bá jáde síta
nínú ọ̀fìn ní à ó mú
nínú okùn dídè nítorí tí
èmi yóò mú wá sórí
Moabu àní ọdún ìjìyà rẹ,”
ní Olúwa wí.
45“Ní abẹ́ òjìji Heṣboni
àwọn tí ó sá dúró láìní agbára,
nítorí iná ti jáde wá láti Heṣboni,
àti ọwọ́ iná láti àárín Sihoni,
yóò sì jó iwájú orí Moabu run,
àti agbárí àwọn ọmọ aláriwo.
46Ègbé ní fún ọ Moabu!
Àwọn ènìyàn orílẹ̀-èdè Kemoṣi ṣègbé
a kó àwọn ọmọkùnrin rẹ lọ sí ilẹ̀ àjèjì
àti àwọn ọmọbìnrin rẹ lọ sí ìgbèkùn.
47“Síbẹ̀, èmi yóò dá ìkólọ
Moabu padà ní ọjọ́ ìkẹyìn,”
ni Olúwa wí.
Eléyìí ní ìdájọ́ ìkẹyìn lórí Moabu.
Profeție împotriva Moabului
1Cu privire la Moab:
Așa vorbește Domnul Oștirilor, Dumnezeul lui Israel:
„Vai de Nebo, căci va fi distrus!
Chiriatayim va fi acoperit de rușine și cucerit!
Întăritura1 Sau: Misgab. va fi acoperită de rușine și zdrobită!
2Moab nu va mai fi lăudat;
la Heșbon2 Heșbon sună asemănător cu termenul ebraic pentru a pune la cale. se plănuiește nimicirea lui:
«Să mergem și să‑l distrugem dintre neamuri!»
Și tu, Madmen2 Madmen sună asemănător cu termenul ebraic pentru a fi redus la tăcere., vei fi redus la tăcere,
căci sabia te va urmări!
3Un strigăt se aude din Horonaim:
«Este prăpăd și mare distrugere!»
4Moab este zdrobit;
se aude strigătul celor mici ai lui.
5Căci pe suișul spre Luhit
plânsul se întețește întruna,
iar pe coborâșul spre Horonaim
se aude strigătul de distrugere al vrăjmașilor.
6Fugiți! Scăpați‑vă viața
și fiți ca un tufar6 Sau: ca Aroer. în pustie!
7Veți fi capturați
pentru că vă încredeți în lucrările și în bogățiile voastre.
Chemoș va merge în captivitate
împreună cu preoții și conducătorii lui.
8Pustiitorul va veni împotriva fiecărei cetăți
și niciuna nu va scăpa.
Valea va deveni o ruină
și podișul va fi nimicit,
căci Domnul a vorbit.
9Presărați sare asupra Moabului,
căci va fi pustiit!9 Sensul celor două versuri este nesigur. Sau Dați niște aripi Moabului / ca să plece zburând!
Cetățile lui vor deveni o pustie
și nimeni nu va mai locui în ele.
10Blestemat să fie cel ce face cu neglijență lucrarea Domnului!
Blestemat să fie cel ce își oprește sabia de la măcel!
11Încă din tinerețea lui, Moabul a fost liniștit,
ca vinul lăsat în drojdia lui;
nu a fost vărsat dintr‑un vas în altul,
nu a fost dus în captivitate.
De aceea i s‑a păstrat gustul
și nu i s‑a schimbat aroma.
12Dar, iată, vin zile, zice Domnul,
când voi trimite oameni să‑l verse din vasul lui,
și ei îl vor vărsa;
îi vor goli vasele
și‑i vor sparge urcioarele.
13Atunci Moabului îi va fi rușine cu Chemoș,
așa cum și Casei lui Israel i‑a fost rușine
de încrederea lor în vițelul de la Betel13 Vezi 1 Regi 12:25-33..
14Cum puteți să ziceți: «Noi suntem viteji,
bărbați curajoși în luptă!»?
15Moabul va fi distrus și cetățile lui vor fi invadate.
Tinerii lui aleși vor fi înjunghiați,
zice Împăratul, al Cărui Nume este Domnul Oștirilor.
16Pieirea Moabului este aproape,
nenorocirea lui vine în grabă mare.
17Bociți‑l, voi, toți cei din jurul lui,
toți aceia care‑i cunoașteți faima!
Ziceți: «Cum a fost sfărâmat sceptrul cel puternic,
toiagul cel glorios!»
18Coboară‑te din slava ta
și așază‑te pe pământ uscat,
locuitor al fiicei Dibonului,
căci pustiitorul Moabului
se va ridica împotriva ta
și‑ți va distruge fortărețele!
19Stai lângă drum și pândește,
locuitoare a Aroerului!
Întreabă pe cel ce fuge
și pe cea care‑și scapă viața,
întreabă: «Ce se întâmplă?»
20Moabul este făcut de rușine, căci este zdrobit.
Gemeți și strigați!
Vestiți de‑a lungul Arnonului
că Moabul este distrus.
21A venit judecata împotriva țării din podiș,
împotriva Holonului, Iahței și Mefaatului,
22împotriva Dibonului,
Neboului și Bet‑Diblataimului,
23împotriva Chiriatayimului,
Bet‑Gamulului și Bet‑Meonului,
24împotriva Cheriotului, împotriva Boțrei,
împotriva tuturor cetăților din țara Moabului,
de departe sau de aproape.
25Cornul25 Coarnele sunt armele de bază și ornamentele unui animal, mărimea și condiția acestora fiind indiciul puterii, al poziției și al sănătății/virilității lui. Prin urmare, cornul a ajuns să reprezinte în Biblie puterea, demnitatea și autoritatea, precum și victoria în luptă. În multe basoreliefuri mesopotamieme regii și zeitățile apar purtând coroane cu coarne pe ele. De asemenea, cornul se referă și la posteritate, la urmașii cuiva (vezi 2 Sam. 2:1; 1 Cron. 25:5; Ps. 132:17). Moabului este tăiat
și brațul lui este zdrobit,
zice Domnul.“
26Îmbătați‑l,
căci s‑a îngâmfat împotriva Domnului!
Tăvălească‑se Moab în vărsătura lui
și să ajungă o pricină de râs!
27N‑a fost Israel o pricină de râs pentru tine?
Se găsește el oare printre hoți
pentru ca ori de câte ori vorbești despre el
să clatini din cap în semn de batjocură?
28Părăsiți cetățile și sălășluiți printre stânci,
locuitori ai Moabului!
Fiți ca un porumbel care‑și face cuib
chiar la marginile unui defileu!
29Noi am auzit de trufia Moabului –
el este foarte mândru.
Am auzit de înfumurarea lui, de trufia lui, de semețirea lui
și de îngâmfarea inimii lui.
30„Știu, zice Domnul.
Aroganța lui este fără temei;
flecăriile lui au înfăptuit ceea ce este fără temei.
31De aceea, gem pentru Moab
și strig pentru întregul Moab.
El suspină pentru oamenii din Chir-Hareset31, 36 Ebr.: Chir Heres o variantă a lui Chir-Hareset..
32Plâng pentru tine, vie din Sibma,
mai mult decât pentru Iazer.
Ramurile tale se întindeau până dincolo de mare,
ajungând până la Iazer32 Cf. Is. 16:8; TM: până la marea Iazerului.,
dar pustiitorul s‑a năpustit
asupra fructelor tale de vară și asupra strugurilor tăi.
33S‑a dus bucuria și veselia
din livezile și de pe câmpiile Moabului.
Am secat vinul din teascuri
și nimeni nu mai calcă teascul cu strigăte de bucurie.
Se aud strigăte de război,
nu strigăte de bucurie.
34Vuietul strigătului lor răsună
din Heșbon până la Eleale și Iahaț,
din Țoar până la Horonaim și Eglat-Șelișia,
căci până și apele Nimrimului sunt secate.
35În Moab voi face ca oamenii să înceteze
să mai aducă jertfe pe înălțimi
și să mai ardă tămâie în cinstea dumnezeilor lor,
zice Domnul.
36De aceea, inima mea jelește ca un fluier pentru Moab,
jelește ca un fluier pentru oamenii din Chir-Hareset,
căci averile pe care le‑au strâns au pierit.
37Toate capetele sunt rase,
toate bărbile sunt tăiate;
toate mâinile au tăieturi
și toate coapsele sunt acoperite cu saci.
38Pe toate acoperișurile Moabului
și în piețe este doar jale,
căci am sfărâmat Moabul
ca pe un vas disprețuit,
zice Domnul.
39Cât este de zdrobit!
Ei gem!
Cum își întoarce Moabul ceafa rușinat!
Moab a devenit o pricină de râs
și de groază pentru toți cei din jur.“
40Așa vorbește Domnul:
„Iată, un vultur se năpustește
și își întinde aripile peste Moab.
41Cheriotul41 Sau: cetățile. va fi cucerit
și fortărețele îi vor fi capturate.
În ziua aceea, inima vitejilor Moabului
va fi ca inima unei femei în durerile nașterii.
42Moabul va fi nimicit dintre popoare
pentru că s‑a îngâmfat împotriva Domnului.
43Groaza, groapa și lațul te așteaptă,
locuitor al Moabului,
zice Domnul.
44Cine va fugi de groază
va cădea în groapă,
și cine se va ridica din groapă
va fi prins în laț,
căci Eu aduc asupra Moabului
anul pedepsei lui,
zice Domnul.
45Fugarii stau fără putere
la umbra Heșbonului,
căci un foc iese din Heșbon,
o flacără iese din mijlocul lui Sihon,
care mistuie fruntea Moabului
și capetele fiilor tumultului.
46Vai de tine, Moabule!
Poporul lui Chemoș este nimicit!
Fiii tăi sunt luați în captivitate
și fiicele tale în exil.
47Dar, în zilele de pe urmă,
îi voi aduce înapoi pe captivii Moabului,
zice Domnul.“
Aici se sfârșește judecata asupra Moabului.