Heberu 6 – YCB & BPH

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Heberu 6:1-20

1Nítorí náà, ó yẹ kí á fi àwọn ẹ̀kọ́ ìgbà tí a ṣẹ̀ṣẹ̀ gba Kristi sílẹ̀, kí á tẹ̀síwájú nínú àwọn ẹ̀kọ́ tí yóò mú wa dàgbàsókè ní pípé. Láìtún ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ máa tẹnumọ́ ẹ̀kọ́ ìpìlẹ̀ bí i ìrònúpìwàdà kúrò nínú òkú iṣẹ́ àti ìgbàgbọ́ nípa ti Ọlọ́run, 2ti ẹ̀kọ́ àwọn bamitiisi, àti ti ìgbọ́wọ́-léni, ti àjíǹde òkú, àti tí ìdájọ́ àìnípẹ̀kun. 3Èyí ní àwa yóò sì ṣe bí Ọlọ́run bá fẹ́.

4Nítorí pé, kò ṣe é ṣe fún àwọn tí a ti là lójú lẹ́ẹ̀kan, tí wọ́n sì ti tọ́ ẹ̀bùn ọ̀run wò, tí wọn sì ti di alábápín Ẹ̀mí Mímọ́, 5tí wọn sì tọ́ ọ̀rọ̀ rere Ọlọ́run wò, àti agbára ayé tí ń bọ̀, 6láti tún sọ wọ́n di ọ̀tun sí ìrònúpìwàdà bí wọn bá ṣubú kúrò; nítorí tí wọ́n tún kan Ọmọ Ọlọ́run mọ́ àgbélébùú sí ara wọn lọ́tun, wọ́n sì dójútì í ní gbangba. 7Nítorí ilẹ̀ tí ó ń fa omi òjò tí ń rọ̀ sórí rẹ̀ nígbà gbogbo mu, tí ó sì ń hu ewébẹ̀ tí ó dára fún àwọn tí à ń tìtorí wọn ro ó pẹ̀lú, ń gba ìbùkún lọ́wọ́ Ọlọ́run. 86.8: Gẹ 3.17-18.Ṣùgbọ́n bí ó ba ń hu ẹ̀gún àti òṣùṣú yóò di kíkọ̀sílẹ̀, kò si jìnnà sí fífi gégùn ún, òpin èyí tí yóò wà fún ìjóná.

9Ṣùgbọ́n olùfẹ́, àwa ní ohun tí ó dára jù bẹ́ẹ̀ lọ, ní tiyín, àti ohun tí ó fi ara mọ́ ìgbàlà, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé à ń ṣe báyìí sọ̀rọ̀. 10Nítorí Ọlọ́run kì í ṣe aláìṣòdodo tí yóò fi gbàgbé iṣẹ́ yin àti ìfẹ́ tí ẹ̀yin fihàn sí orúkọ rẹ̀, nípa iṣẹ́ ìránṣẹ́ tí ẹ ti ṣe fún àwọn ènìyàn mímọ́, tí ẹ sì tún ń ṣe. 11Àwa sì fẹ́ kí olúkúlùkù yín máa fi irú àìsimi kan náà hàn, fún ẹ̀kún ìdánilójú ìrètí títí dé òpin. 12Kí ẹ má ṣe di onílọ̀ra, ṣùgbọ́n aláfarawé àwọn tí wọn ti ipa ìgbàgbọ́ àti sùúrù jogún àwọn ìlérí.

Ìdánilójú ìlérí Ọlọ́run

136.13-14: Gẹ 22.16-17.Nítorí nígbà tí Ọlọ́run ṣe ìlérí fún Abrahamu, bí kò ti rí ẹni tí ó pọ̀jù òun láti fi búra, ó fi ara rẹ̀ búra, wí pé, 14“Nítòótọ́ ní bíbùkún èmi ó bùkún fún ọ, àti ní bíbísí èmi ó sì mú ọ bí sí i.” 15Bẹ́ẹ̀ náà sì ni, lẹ́yìn ìgbà tí Abrahamu fi sùúrù dúró, ó ri ìlérí náà gbà.

16Nítorí ènìyàn a máa fi ẹni tí ó pọ̀jù wọ́n lọ búra: ìbúra náà a sì fi òpin sí gbogbo ìjiyàn wọn fún ìfẹ̀sẹ̀ múlẹ̀ ọ̀rọ̀. 17Nínú èyí tí Ọlọ́run, ẹni tí ń fẹ́ gidigidi láti fi àìlèyípadà ète rẹ̀ hàn fún àwọn ajogún ìlérí náà, ó fi ìbúra sáàrín wọn. 18Pé, nípa ohun àìlèyípadà méjì, nínú èyí tí kò le ṣe é ṣe fún Ọlọ́run láti ṣèké, kí a lè mú àwa tí ó ti sá sábẹ́ ààbò rẹ̀ ní ọkàn lè láti di ìrètí tí a gbé kalẹ̀ níwájú wa mú ṣinṣin. 196.19: Le 16.2.Èyí tí àwa níbi ìdákọ̀ró ọkàn fún ọkàn wa, ìrètí tí ó dájú tí ó sì dúró ṣinṣin, tí ó sì wọ inú ilé lọ lẹ́yìn aṣọ ìkélé; 206.20: Sm 110.4.níbi tí Jesu, aṣáájú wa ti wọ̀ lọ fún wa, òun sì ni a fi jẹ alábojútó àlùfáà títí láé ní ipasẹ̀ Melkisedeki.

Bibelen på hverdagsdansk

Hebræerbrevet 6:1-20

1Nu vil vi så gå videre med den undervisning, der passer til modne mennesker. Det skulle jo ikke være nødvendigt én gang til at lære jer de mest elementære ting om Kristus, nemlig at man frelses ved troen på Gud og ikke ved nytteløse anstrengelser. 2Det burde også være overflødigt at tale om de forskellige slags dåb, om håndspålæggelse, om opstandelsen fra de døde og om Guds dom, som afgør menneskers evige skæbne. 3Lad os nu gå videre med undervisningen, hvis Gud da tillader det.

Advarsel mod frafald og sløvhed

4-6Når mennesker først har set Guds lys og nydt godt af Himlens velsignelser, og når de har fået Helligåndens kraft og har fået en forsmag på den kommende verdens vidundere, og hvor herligt det er at høre, når Gud taler, og de så alligevel falder fra, da kan man ikke føre dem tilbage til Herren. De har jo derved korsfæstet Guds Søn igen og hånet ham offentligt. 7Når en mark opsuger den regn, som falder på den, og producerer en god høst til gavn for dem, der dyrker jorden, vil den opleve Guds velsignelse. 8Men hvis den derimod frembringer tidsler og tjørnebuske, er den intet værd og vil opleve Guds dom. Det ender med, at man afbrænder den.

9Selvom jeg skriver sådan, kære venner, er jeg overbevist om, at det står bedre til med jer, og at I er på frelsens vej. 10Gud er ikke uretfærdig. Han vil huske jeres arbejde og den kærlighed til ham, som I har vist ved, at I har hjulpet og stadig hjælper jeres medkristne. 11Vi ønsker inderligt, at hver eneste af jer lige til det sidste må fortsætte med begejstret at holde fast ved visheden om den herlighed, der venter jer. 12Så bliver I ikke sløve, men bliver som dem, der ved tro og udholdenhed oplever opfyldelsen af alt, hvad Gud har lovet sine børn.

Guds løfter står urokkeligt fast

13-14I ved, at da Gud lovede Abraham en søn, svor han ved sit eget navn—han havde jo ikke noget større at sværge ved—og sagde til Abraham, at han ville velsigne ham og gøre hans efterkommere talrige.6,13-14 Jf. 1.Mos. 22,16-17. 15Og efter at have ventet med stor tålmodighed fik Abraham til sidst løftet opfyldt.

16Når mennesker sværger på, at de vil gøre et eller andet, sværger de i Guds navn og påkalder Guds straf over sig selv, hvis de bryder deres løfte. At sværge på den måde gør al diskussion overflødig. 17Således garanterede Gud også sit løfte ved at sværge på det, for han ønskede at slå det helt fast over for dem, som løftet gælder, at det er et urokkeligt løfte. 18Der er altså to ting, som slår fast, at løftet vil blive opfyldt: For det første, at det var Gud, der lovede det, og for det andet, at han garanterede løftet ved at sværge på det. Og Gud kan ikke lyve. Det hjælper os, som har søgt tilflugt hos ham, til at holde fast ved visheden om den lovede frelse. 19Visheden om frelse er som et anker for sjælen, et anker, der når helt ind i Guds nærvær, bag forhænget ind til det inderste rum i den himmelske helligdom, hvor det er gjort urokkeligt fast. 20Jesus gik jo forud for os ind i Guds nærvær for dér at tjene som vores evige ypperstepræst efter Melkizedeks forbillede.