Abrahamu àti Abimeleki
1Abrahamu sì kó kúrò níbẹ̀ lọ sí ìhà gúúsù ó sì ń gbé ní agbede-méjì Kadeṣi àti Ṣuri; ó sì gbé ní ìlú Gerari fún ìgbà díẹ̀. 220.2: Gẹ 12.13; 26.7.Abrahamu sì sọ ní ti Sara aya rẹ̀ níbẹ̀ pé, “Arábìnrin mi ni.” Abimeleki ọba Gerari sì ránṣẹ́ mú Sara wá sí ààfin rẹ̀.
3Ṣùgbọ́n Ọlọ́run tọ Abimeleki wá ní ojú àlá lọ́jọ́ kan, ó sì wí fún un pé, “Kíyèsi, kò sí ohun tí o fi sàn ju òkú lọ, nítorí obìnrin tí ìwọ mú sọ́dọ̀ n nì, aya ẹni kan ní íṣe.”
4Ṣùgbọ́n Abimeleki kò tí ìbá obìnrin náà lòpọ̀, nítorí náà ó wí pé, “Olúwa ìwọ yóò run orílẹ̀-èdè aláìlẹ́bi bí? 5Ǹjẹ́ òun kò sọ fún mi pé, ‘Arábìnrin mi ni,’ obìnrin náà pẹ̀lú sì sọ pé, ‘Arákùnrin mí ni’? Ní òtítọ́ pẹ̀lú ọkàn mímọ́ àti ọwọ́ mímọ́, ni mo ṣe èyí.”
6Nígbà náà ni Ọlọ́run wí fún un nínú àlá náà pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, mo mọ̀ pé pẹ̀lú òtítọ́ inú ni ìwọ ṣe èyí, èyí ni mo fi pa ọ́ mọ́ tí ń kò jẹ́ kí o ṣẹ̀ sí mi. Ìdí nìyí tí n kò fi jẹ́ kí o ní ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin náà. 7Nísinsin yìí, dá aya ọkùnrin náà padà, nítorí pé wòlíì ni, yóò sì gbàdúrà fún ọ, ìwọ yóò sì yè. Ṣùgbọ́n bí ìwọ kò bá dá a padà, mọ̀ dájú pé ìwọ àti gbogbo ẹni tí í ṣe tìrẹ yóò kú.”
8Ní òwúrọ̀ kùtùkùtù ọjọ́ kejì, Abimeleki pe gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀. Nígbà tí ó sì sọ gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún wọn, ẹ̀rù bà wọ́n gidigidi. 9Nígbà náà ni Abimeleki pe Abrahamu ó sì wí fún un pé, “Èwo ni èyí tí ìwọ ṣe sí wa yìí? Ẹ̀ṣẹ̀ wo ni mo ṣẹ̀ ọ́ tí ìwọ fi mú ìdálẹ́bi ńlá wá sí orí èmi àti ìjọba mi? Kò yẹ kí ìwọ hu irú ìwà yìí sí mi.” 10Abimeleki sì bi Abrahamu pé, “Kín ló dé tí ìwọ fi ṣe èyí?”
11Abrahamu sì dáhùn pé, “Mo ṣe èyí nítorí mo rò nínú ara mi pé, ẹ̀yin tí ẹ wà níhìn-ín, ẹ kò bẹ̀rù Ọlọ́run, pé, ẹ sì le pa mí nítorí aya mi. 12Yàtọ̀ fún ìyẹn, òtítọ́ ni pé arábìnrin mi ni. Ọmọ baba kan ni wá, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, a kì í ṣe ọmọ ìyá kan. Mo sì fẹ́ ẹ ní aya. 13Nígbà tí Ọlọ́run sì mú mi rìn kiri kúrò ní ilé baba mi, mo wí fún un pé, ‘Èyí ni ọ̀nà tí ó lè gbà fihàn pé ó fẹ́ràn mi. Gbogbo ibi tí a bá dé máa sọ pé, “Arákùnrin rẹ ni mí.” ’ ”
14Nígbà náà ni Abimeleki mú àgùntàn àti màlúù wá, àti ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin, ó sì kó wọn fún Abrahamu, ó sì dá Sara aya rẹ̀ padà fún un. 15Abimeleki sì tún wí fún un pé, “Gbogbo ilẹ̀ mí nìyí níwájú rẹ, máa gbé ní ibikíbi tí o fẹ́ níbẹ̀.”
16Abimeleki sì wí fún Sara pé, “Mo fi ẹgbẹ̀rún (1,000) owó ẹyọ fàdákà fún arákùnrin rẹ. Èyí ni owó ìtánràn ẹ̀ṣẹ̀ mi sí ọ níwájú gbogbo ẹni tí ó wà pẹ̀lú rẹ àti pé, a dá ọ láre pátápátá.”
17Nígbà náà, Abrahamu gbàdúrà sí Ọlọ́run, Ọlọ́run sì wo Abimeleki àti aya rẹ̀ àti àwọn ẹrúbìnrin rẹ̀ sàn. Wọ́n sì tún ń bímọ, 18nítorí Olúwa ti sé gbogbo ará ilé Abimeleki nínú nítorí Sara aya Abrahamu.
Iburahĩmu na Abimeleku
120:1 Kĩam 18:1; Kĩam 16:7Na rĩrĩ, Iburahĩmu nĩoimire kũu aarĩ, agĩthiĩ mwena wa Negevu, na agĩtũũra gatagatĩ ga Kadeshi na Shuri. Gwa kahinda nĩatũũrire Gerari 220:2 Kĩam 12:13; Kĩam 12:15na arĩ kũu Iburahĩmu oigaga atĩrĩ ha ũhoro wa mũtumia wake Sara, “Ũyũ nĩ mwarĩ wa baba.” Tondũ ũcio Abimeleku mũthamaki wa Gerari agĩtũmanĩra Sara na akĩmuoya.
320:3 Ndar 22:9, 20; Ndar 12:6; Ayub 33:15No rĩrĩ, Ngai akiumĩrĩra Abimeleku ũtukũ na kĩroto, akĩmwĩra atĩrĩ, “Wee-rĩ, no ta ũkuĩte tondũ mũndũ-wa-nja ũcio woete nĩ mũtumia wene.”
420:4 Kĩam 18:25No Abimeleku ndaakoretwo akuhĩrĩirie Sara, nĩ ũndũ ũcio akĩũria atĩrĩ, “Mwathani, no wanange rũrĩrĩ rũtehĩtie? 520:5 Kĩam 12:19; Thab 7:8; 25:21; 26:6; 41:12Githĩ ti we wanjĩĩrire, ‘Ũyũ nĩ mwarĩ wa baba?’ Na ningĩ o nake Sara githĩ ndoigire atĩrĩ, ‘Ũyũ nĩ mũrũ wa baba?’ Njĩkĩte ũndũ ũcio na ũrũngĩrĩru wa ngoro na moko matarĩ ũcuuke.”
620:6 1Sam 25:26, 34; Thab 41:4; 51:4Ningĩ Ngai akĩmwĩra atĩrĩ kĩroto-inĩ, “Ĩĩ, nĩnjũũĩ ũrekĩte ũguo na ũrũngĩrĩru wa ngoro, na nĩkĩo ndĩrakũgiririe ũnjĩhĩrie. Nĩkĩo itanareka ũmũhutie. 720:7 Kĩam 20:17; 1Sam 7:5; Ayub 42:8Rĩu-rĩ, cookeria mũndũ ũcio mũtumia wake, nĩgũkorwo nĩ mũnabii, nake nĩegũkũhooera, na nĩũgũtũũra muoyo. No waga kũmũcookia-rĩ, ũmenye ti-itherũ wee nĩũgũkua, na andũ aku othe nĩmegũkua.”
8Mũthenya ũyũ ũngĩ rũciinĩ tene, Abimeleku agĩtũmanĩra anene ake othe, na aarĩkia kũmeera maũndũ marĩa mothe meekĩkĩte, andũ acio magĩĩtigĩra mũno. 920:9 Kĩam 12:18; 34:7Abimeleku agĩcooka agĩĩta Iburahĩmu na akĩmũũria atĩrĩ, “Nĩ atĩa ũguo ũtwĩkĩte? Nĩ atĩa ngwĩhĩirie, nĩguo ũndeherere niĩ na ũthamaki wakwa ũũru mũnene ũguo? Ũnjĩkĩte maũndũ mataagĩrĩire gwĩkwo.” 10Ningĩ Abimeleku akĩũria Iburahĩmu atĩrĩ, “Nĩ kĩĩ gĩatũmire wĩke ũguo?”
1120:11 Kĩam 12:12; Thab 36:1Iburahĩmu akĩmũcookeria atĩrĩ, “Ndeĩrire atĩrĩ, ‘Kũndũ gũkũ andũ matiĩtigĩrĩte Ngai, na nĩmekũnjũraga nĩ ũndũ wa mũtumia wakwa.’ 1220:12 Kĩam 12:13O na kũrĩ ũguo, ti-itherũ nĩ mwarĩ wa-baba, mũirĩtu wa baba; no tũtirĩ a nyina ũmwe, nĩkĩo aatuĩkire mũtumia wakwa. 13Na rĩrĩa Ngai aandutire kuuma nyũmba-inĩ ya baba thiĩ ngorũũrage, ndeerire mũtumia wakwa atĩrĩ, ‘Ũũ nĩguo ũrĩnyonagia wendo waku: Kũrĩa guothe tũrĩthiiaga, uugage atĩrĩ ũhoro-inĩ ũnjĩgiĩ, “Ũyũ nĩ mũrũ wa baba.” ’ ”
1420:14 Kĩam 12:16Iburahĩmu aarĩkia kwaria, Abimeleku akĩruta ngʼondu na ngʼombe, na ngombo cia arũme na cia andũ-a-nja, na agĩcihe Iburahĩmu, na akĩmũcookeria Sara mũtumia wake. 1520:15 Kĩam 13:9Ningĩ Abimeleku akĩmwĩra atĩrĩ, “Bũrũri wakwa ũrĩ mbere yaku; tũũra harĩa hothe ũngĩenda.”
16Nake Abimeleku akĩĩra Sara atĩrĩ, “Nĩngũhe mũrũ-wa-thoguo cekeri 1,000 cia betha20:16 nĩ ta kilo ikũmi na ĩmwe na nuthu (11.5). ituĩke cia kũrĩhĩria ihĩtia rĩrĩa ũhĩtĩirio mbere ya andũ aya othe mũrĩ nao; we ndũrĩ ũũru wĩkĩte.”
17Nake Iburahĩmu akĩhooya Ngai, nake Ngai akĩhonia Abimeleku, na mũtumia wake, na ngombo ciake cia airĩtu nĩguo mahote gũciara ciana rĩngĩ, 1820:18 Kĩam 12:17nĩgũkorwo Jehova nĩahingĩte nda cia andũ-a-nja othe a nyũmba ya Abimeleku, makaaga kũgĩa ciana, nĩ ũndũ wa Abimeleku kuoya Sara mũtumia wa Iburahĩmu.