Ìṣe àwọn Aposteli 1 – YCB & GKY

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Ìṣe àwọn Aposteli 1:1-26

A mú Jesu lọ sí ọ̀run

11.1: Lk 1.1-4.Nínú ìwé mi ìṣáájú, Teofilu, ni mo ti kọ ní ti ohun gbogbo tí Jesu bẹ̀rẹ̀ sí ṣe àti kọ́ 2títí ó fi di ọjọ́ tí a gbà á lọ sókè ọ̀run, lẹ́yìn tí ó ti ti ipa Ẹ̀mí Mímọ́ pàṣẹ fún àwọn aposteli tí ó yàn. 3Lẹ́yìn ìjìyà rẹ̀, ó fi ara rẹ̀ hàn fún wọn àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀rí tí ó dájú pé òun wà láààyè. Ó fi ara hàn wọ́n fún ogójì ọjọ́, ó sì sọ̀rọ̀ nípa ìjọba Ọlọ́run. 41.4: Lk 24.49.Ní àkókò kan bí ó sì ti ń jẹun pẹ̀lú wọn, ó pàṣẹ yìí fún wọn, “Ẹ má ṣe kúrò ní Jerusalẹmu, ṣùgbọ́n ẹ dúró de ìlérí tí Baba mi ṣe ìlérí, èyí tí ẹ̀yin tí gbọ́ lẹ́nu mi. 5Nítorí Johanu fi omi bamitiisi yín, ṣùgbọ́n ní ọjọ́ díẹ̀ sí i, a o fi Ẹ̀mí Mímọ́ bamitiisi yín.”

6Nítorí náà, nígbà tí wọ́n sì péjọpọ̀, wọn bi í léèrè pé, “Olúwa, láti ìgbà yí lọ ìwọ yóò ha mú ìjọba padà fún Israẹli bí?”

7Ó sì wí fún wọn pé, “Kì í ṣe tiyín ni láti mọ àkókò tàbí ìgbà tí Baba ti yàn nípa àṣẹ òun tìkára rẹ̀. 81.8: Lk 24.48-49.Ṣùgbọ́n ẹ̀yin yóò gba agbára, nígbà tí Ẹ̀mí Mímọ́ bá bà lé e yín; ẹ̀yin yóò sì máa ṣe ẹlẹ́rìí mi ni Jerusalẹmu, àti ní gbogbo Judea, àti ní Samaria, àti títí dé òpin ilẹ̀ ayé.”

91.9-12: Lk 24.50-53.Nígbà tí ó sì tí wí nǹkan wọ̀nyí, a gbà á sókè lójú wọn; ìkùùkuu àwọsánmọ̀ sì gbà á kúrò lójú wọn.

10Bí wọ́n sì ti tẹjúmọ́ ojú ọ̀run bí ó ti ń lọ sókè, lójijì, àwọn ọkùnrin méjì tí ó wọ aṣọ funfun dúró létí ọ̀dọ̀ wọn. 11Wọ́n sì wí pé, “Ẹ̀yin ara Galili, èéṣe tí ẹ̀yin fi dúró tí ẹ̀ ń wo ojú ọ̀run? Jesu yìí, tí a gbà sókè ọ̀run kúrò lọ́wọ́ yín, yóò padà bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ ti rí tí ó ń lọ sì ọ̀run.”

A yan Mattia Rọ́pò Judasi

12Lẹ́yìn náà ni wọ́n padà sí Jerusalẹmu láti orí òkè ti a ń pè ni olifi, tí ó tó ìwọ̀n ìrìn ọjọ́ ìsinmi kan. 131.13: Mt 10.2-4; Mk 3.16-19; Lk 6.14-16.Nígbà tí wọn sì wọlé, wọn lọ sí iyàrá òkè, níbi tí wọ́n ń gbé. Àwọn tó wà níbẹ̀ ni:

Peteru, Jakọbu, Johanu àti Anderu;

Filipi àti Tomasi;

Bartolomeu àti Matiu;

Jakọbu ọmọ Alfeu, Simoni Sealoti, àti Judasi arákùnrin Jakọbu.

14Gbogbo àwọn wọ̀nyí pẹ̀lú àwọn obìnrin àti Maria ìyá Jesu àti àwọn arákùnrin rẹ̀ fi ọkàn kan dúró láti máa gbàdúrà.

15Ní ọjọ́ wọ̀nyí ni Peteru sí dìde dúró láàrín àwọn ọmọ-ẹ̀yìn (iye àwọn ènìyàn wọ̀nyí jẹ́ ọgọ́fà) 161.16-19: Mt 27.3-10.ó wí pé, “Ẹ̀yin ará, ìwé mímọ́ kò lè ṣe kí ó má ṣẹ, èyí tí Ẹ̀mí Mímọ́ ti sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu Dafidi nípa Judasi, tí ó ṣe atọ́nà fún àwọn tí ó mú Jesu. 17Nítorí ọ̀kan nínú wa ni òun ń ṣe tẹ́lẹ̀, òun sì ní ìpín nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́ yìí.”

18(Judasi fi èrè àìṣòótọ́ rẹ̀ ra ilẹ̀ kan; nígbà tí ó sì ṣubú ni ògèdèǹgbé, ó bẹ́ ní agbede-méjì, gbogbo ìfun rẹ̀ sì tú jáde. 19Ó si di mí mọ̀ fún gbogbo àwọn ti ń gbé Jerusalẹmu; nítorí náà ni wọ́n fi ń pè ilẹ̀ náà ni Alkedama ní èdè wọn, èyí sì ni, Ilẹ̀ Ẹ̀jẹ̀.)

201.20: Sm 69.25; 109.8.Peteru sì wí pé, “Nítorí a ti kọ ọ́ nípa rẹ̀ nínú Ìwé Saamu pé,

“ ‘Jẹ́ ki ibùgbé rẹ̀ di ahoro,

kí ẹnikẹ́ni má ṣe gbé inú rẹ̀,’

àti,

“ ‘Ipò rẹ̀ ni kí ẹlòmíràn kí ó gbà.’

21Nítorí náà, ó di dandan láti yan ọ̀kan nínú àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ti ń bá wa rìn ni gbogbo àkókò tí Jesu Olúwa ń wọlé, tí ó sì jáde láàrín wa. 22Bẹ́ẹ̀ láti ìgbà bamitiisi Johanu títí ó fi di ọjọ́ náà ti a gbe é lọ sókè kúrò lọ́dọ̀ wa. Ó yẹ kí ọ̀kan nínú àwọn wọ̀nyí ṣe ẹlẹ́rìí àjíǹde rẹ̀ pẹ̀lú wa.”

23Wọn sì yan àwọn méjì, Josẹfu tí a ń pè ní Barsaba (ẹni tí a sọ àpèlé rẹ̀ ni Justu) àti Mattia. 24Wọn sì gbàdúrà, wọn sì wí pé, “Olúwa, ìwọ mọ ọkàn gbogbo ènìyàn, fihàn wá nínú àwọn méjì yìí, èwo ni ìwọ yàn 25kí ó lè gba ipò nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́ aposteli yìí, èyí tí Judasi kúrò nínú rẹ̀, ki òun kí ó lè lọ sí ipò ti ara rẹ̀.” 26Wọ́n sì dìbò fún wọn; ìbò sí mú Mattia; a sì kà á mọ́ àwọn aposteli mọ́kànlá.

Holy Bible in Gĩkũyũ

Atũmwo 1:1-26

Jesũ Kuoywo Athiĩ Igũrũ

11:1 Luk 1:1-4Thĩinĩ wa ibuku rĩakwa rĩa mbere, wee Theofilo-rĩ, nĩndakwandĩkĩire maũndũ mothe marĩa Jesũ aambĩrĩirie gwĩka na kũrutana 21:2 Math 28:19, 20; Mar 16:19nginya mũthenya ũrĩa oirwo agĩtwarwo igũrũ thuutha wa kũhe atũmwo arĩa aathuurĩte mawatho na ũndũ wa Roho Mũtheru. 31:3 Math 28:17; Mar 1:4Thuutha wa kũnyariirĩka gwake, akĩĩonania kũrĩ andũ acio na akĩheana imenyithia nyingĩ cia kuonania atĩ aarĩ muoyo. Nĩamoimĩrĩire ihinda rĩa mĩthenya mĩrongo ĩna, na akĩaria ũhoro ũkoniĩ ũthamaki wa Ngai. 41:4 Luk 24:49; Joh 14:16Hĩndĩ ĩmwe, rĩrĩa aarĩĩanagĩra nao, nĩamathire, akĩmeera atĩrĩ: “Mũtikoime Jerusalemu, no etererai kĩheo kĩrĩa Ithe witũ eeranĩire, o kĩrĩa inyuĩ mwanaigua ngĩaria ũhoro wakĩo. 51:5 Mar 1:4Nĩgũkorwo Johana aabatithanagia na maaĩ, no inyuĩ mũrĩbatithio na Roho Mũtheru mĩthenya mĩingĩ ĩtaanathira.”

6Nĩ ũndũ ũcio rĩrĩa maagomanire hamwe makĩmũũria atĩrĩ, “Mwathani, ihinda rĩĩrĩ nĩrĩo ũgũcookeria andũ a Isiraeli ũthamaki wao?”

71:7 Gũcook 29:29; Math 24:36Nake akĩmeera atĩrĩ: “Ti ũhoro wanyu kũmenya ciathĩ o na kana mahinda marĩa Ithe witũ atuĩte na ũhoti wake mwene. 81:8 Atũm 2:1-4; Luk 24:48No nĩmũrĩheo hinya rĩrĩa Roho Mũtheru arĩũka igũrũ rĩanyu; na inyuĩ nĩmũgatuĩka aira akwa thĩinĩ wa Jerusalemu, na Judea guothe, na Samaria, na nginya ituri ciothe cia thĩ.”

91:9 Atũm 1:2Aarĩkia kuuga ũguo, akĩoywo na igũrũ o meroreire, narĩo itu rĩkĩmũhumbĩra magĩtiga kũmuona rĩngĩ.

101:10 Joh 20:12O hĩndĩ ĩyo maikarĩte macũthĩrĩirie mũno akĩambata matu-inĩ-rĩ, o rĩmwe andũ eerĩ mehumbĩte nguo njerũ makĩrũgama o hau maarĩ. 11Makĩmooria atĩrĩ, “Andũ aya a Galili,1:11 Arutwo a Jesũ othe moimĩte Galili tiga o Judasi, no hĩndĩ ĩno nĩeyũragĩte. mũrũgamĩte haha mũcũthĩrĩirie igũrũ nĩkĩ? Jesũ o ro ũcio, ũrĩa weherio harĩ inyuĩ aatwarwo igũrũ-rĩ, agaacooka o ro ũguo mwamuona agĩthiĩ.”

Mathia Gũthuurwo Acooke Ithenya rĩa Judasi

121:12 Luk 24:52; Arom 7:1Hĩndĩ ĩyo magĩcooka Jerusalemu moimĩte Kĩrĩma-inĩ kĩa Mĩtamaiyũ,1:12 Kĩrĩma gĩkĩ kĩarĩ gatagatĩ ka Jerusalemu na Bethania. Ayahudi matietĩkĩrĩtio gũthiĩ rũgendo rũraihu mũthenya wa Thabatũ. mũigana wa rũgendo rũrĩa rũngĩathiirwo mũthenya wa Thabatũ kuuma itũũra inene. 131:13 Atũm 9:37; 20:8; Luk 6:14-16Rĩrĩa maakinyire, makĩambata nyũmba ya igũrũ ĩrĩa maikaraga. Nao andũ arĩa maarĩ ho maarĩ Petero, na Johana, na Jakubu na Anderea; Filipu na Toma, na Baritholomayo na Mathayo; Jakubu mũrũ wa Alufayo, na Simoni Mũzelote, na Judasi mũrũ wa Jakubu. 141:14 Atũm 2:42; Luk 23:49, 55Othe makĩnyiitanĩra hamwe, makĩrũmanĩrĩria kũhooya, hamwe na atumia, na Mariamu nyina wa Jesũ, o na ariũ a nyina na Jesũ.

15Na rĩrĩ, matukũ-inĩ macio Petero akĩrũgama gatagatĩ-inĩ ka andũ arĩa meetĩkĩtie (gĩkundi kĩa andũ ta igana rĩa mĩrongo ĩĩrĩ), 16akiuga atĩrĩ, “Ariũ na aarĩ a Ithe witũ, Maandĩko no nginya mangĩahingire marĩa Roho Mũtheru aaririe tene na kanua ka Daudi ũhoro ũkoniĩ Judasi, ũrĩa watongoririe andũ arĩa maanyiitire Jesũ. 171:17 Joh 6:70, 71Aarĩ ũmwe witũ na nĩagwatanagĩra na ithuĩ ũtungata-inĩ ũyũ.”

181:18 Math 26:14, 15; Math 27:3-10(Judasi nĩagũrire gĩthaka na kĩheo kĩrĩa aamũkĩrire nĩ ũndũ wa waganu wake. Nake akĩgũa gĩthaka-inĩ kĩu na mũnduru, nayo nda yake ĩgĩtathũka, namo mara mothe makiuma. 19Andũ othe a kũu Jerusalemu makĩigua ũhoro ũcio, na nĩ ũndũ ũcio magĩĩta gĩthaka kĩu na rũthiomi rwao Ekiladama, ũguo nĩ kuuga, Gĩthaka kĩa Thakame.)

201:20 Thab 69:25; Thab 109:8“Nĩgũkorwo nĩ kwandĩkĩtwo Ibuku-inĩ rĩa Thaburi atĩrĩ,

“ ‘Mũciĩ wake ũrokira ihooru;

kũroaga mũndũ wa gũtũũra kuo,’

ningĩ gũkaandĩkwo atĩrĩ,

“ ‘Ũtongoria wake ũrooywo nĩ mũndũ ũngĩ.’

21Nĩ ũndũ ũcio nĩ kwagĩrĩire gũthuurwo mũndũ ũmwe kuuma kũrĩ andũ arĩa makoretwo marĩ hamwe na ithuĩ ihinda rĩothe rĩrĩa Mwathani Jesũ aaceeraga na ithuĩ, 221:22 Mar 1:4; Luk 24:48kwambĩrĩria hĩndĩ ya ũbatithio wa Johana nginya hĩndĩ ĩrĩa Jesũ oirwo akĩambata akĩehera harĩ ithuĩ. Nĩgũkorwo mũndũ ũmwe wa aya no nginya atuĩke mũira hamwe na ithuĩ ũhoro-inĩ wa kũriũka gwake.”

23Nĩ ũndũ ũcio makĩrũgamia andũ eerĩ, Jusufu ũrĩa wetagwo Barasaba1:23 Barasaba nĩ kuuga “Mũrũ wa Thabatũ.” (na no oĩkaine ta Jusito), na Mathia. 241:24 Kũg 2:23; 1Sam 14:41Magĩcooka makĩhooya makiuga atĩrĩ, “Mwathani, wee nĩũũĩ ngoro ya mũndũ wothe. Tuonie nũũ wa aya eerĩ ũthuurĩte 25nĩguo oe ũtungata ũyũ wa gũtuĩka mũtũmwo, ũrĩa Judasi aatigire nĩguo athiĩ kũrĩa kũrĩ gwake.” 26Magĩcooka magĩcuuka mĩtĩ, naguo mũtĩ ũkĩgwĩra Mathia; nĩ ũndũ ũcio akĩongererwo harĩ atũmwo acio ikũmi na ũmwe.