የእስራኤል ዐርነት መውጣት
1በዚያ ቀን እግዚአብሔር፣
ተወርዋሪውን እባብ ሌዋታንን፣
የሚጠቀለለውን ዘንዶ ሌዋታንን
በብርቱ፣ በታላቁና በኀይለኛ ሰይፍ ይቀጣዋል፤
የባሕሩንም ግዙፍ አውሬ ይቈራርጠዋል።
2በዚያን ቀን እንዲህ ይባላል፤
“ለመልካሙ የወይን ቦታ ዘምሩለት፤
3እኔ እግዚአብሔር ጠባቂው ነኝ፤
ዘወትር ውሃ አጠጣዋለሁ፤
ስለዚህ ማንም አይጐዳውም፣
ቀንና ሌሊት እጠብቀዋለሁ፤
4እኔ አልቈጣም።
እሾኽና ኵርንችት ምነው በተነሡብኝ!
ለውጊያ በወጣሁባቸው፣
አንድ ላይ ባቃጠልኋቸው!
5አለዚያ ይምጡና መሸሸጊያቸው ያድርጉኝ፤
ከእኔ ጋር ሰላም ይፍጠሩ፤
አዎን፤ ከእኔ ጋር ሰላም ያድርጉ።”
6በሚመጡት ቀናት ያዕቆብ ሥር ይሰድዳል፤
እስራኤልም ያቈጠቍጣል፣ ያብባልም፤
በፍሬያቸውም ምድርን ሁሉ ይሞላሉ።
7የመቷትን እንደ መታቸው፣
እግዚአብሔር እርሷንስ መታትን?
የገደሏትን እንደ ገደላቸው፣
እርሷስ ተገደለችን?
8በጦርነትና በስደት ተፋለምሃት27፥8 በዕብራይስጡ የዚህ ሐረግ ትርጕም በትክክል አይታወቅም።፤
የምሥራቅ ነፋስ እንደሚነፍስበት ቀን፣
በብርቱ ዐውሎ ነፋስ አሳደድሃት።
9ያዕቆብ የመሠዊያ ድንጋዮችን፣
እንደ ኖራ ድንጋይ ፈጭቶ ሲያደቅቃቸው፣
የአሼራን ዐምድና የዕጣን መሠዊያዎችን፣
ከቦታቸው ነቅሎ ሲጥል፣
በዚያን ጊዜ በደሉ ይሰረይለታል፤
ይህም ኀጢአቱን የማስወገዱ ሙሉ ፍሬ ይሆናል።
10የተመሸገባት ከተማ ባዶዋን ቀርታለች፤
እንደ ምድረ በዳም የተተወች ስፍራ ሆናለች፤
ጥጆች በዚያ ይሰማራሉ፤
እዚያም ይተኛሉ፤
ቅርንጫፎቿንም ልጠው ይበላሉ።
11ጫፎቿ ሲደርቁ ይሰበራሉ፤
ሴቶችም መጥተው ይማግዷቸዋል።
ማስተዋል የሌለው ሕዝብ ስለሆነ፣
ፈጣሪው አይራራለትም፤
ያበጀውም አይምረውም።
12በዚያ ቀን ከኤፍራጥስ ወንዝ አንሥቶ እስከ ግብፅ ደረቅ ወንዝ፣ እግዚአብሔር እህሉን ይወቃል፤ እናንተም የእስራኤል ልጆች ሆይ፤ አንድ በአንድ ትሰበሰባላችሁ። 13በዚያ ቀን ታላቅ መለከት ይነፋል፤ በአሦር የጠፉትና በግብፅ የተሰደዱትም መጥተው፣ በተቀደሰው ተራራ በኢየሩሳሌም እግዚአብሔርን ያመልካሉ።
Ìdáǹdè Israẹli
1Ní ọjọ́ náà,
Olúwa yóò fi idà rẹ̀ jẹ ni ní yà
idà rẹ̀ a mú bí iná tí ó tóbi tí ó sì lágbára
Lefitani ejò tí ń yọ̀ tẹ̀ẹ̀rẹ̀ n nì,
Lefitani ejò tí ń lọ́ bìrìkìtì;
Òun yóò sì pa ẹ̀mí búburú inú Òkun náà.
2Ní ọjọ́ náà,
“Kọrin nípa ọgbà àjàrà eléso kan.
3Èmi Olúwa ń bojútó o,
Èmi ó bomirin ín láti ìgbàdégbà.
Èmi ó ṣọ́ ọ tọ̀sán tòru
kí ẹnikẹ́ni má ba à pa á lára.
4Inú kò bí mi.
Bí ẹ̀gún àti ẹ̀wọ̀n bá dojú ìjà kọ mí!
Èmi yóò dìde sí wọn ní ogun,
Èmi yóò sì dáná sun gbogbo wọn.
5Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, jẹ́ kí wọn wá sọ́dọ̀ mi fún ààbò;
jẹ́ kí wọ́n wá àlàáfíà pẹ̀lú mi,
bẹ́ẹ̀ ni, jẹ́ kí wọn wá àlàáfíà pẹ̀lú mi.”
6Ní ọjọ́ iwájú Jakọbu yóò ta gbòǹgbò,
Israẹli yóò tanná yóò sì rudi
èso rẹ̀ yóò sì kún gbogbo ayé.
7Ǹjẹ́ Olúwa ti lù ú
gẹ́gẹ́ bí ó ti lu àwọn tí ó lù ú bolẹ̀?
Ǹjẹ́ a ti pa á
gẹ́gẹ́ bí a ti pa àwọn tí ó pa á?
8Nípa ogun jíjà àti ìjìyà ti o le ni ó
fi dojúkọ ọ́
pẹ̀lú ìjì gbígbóná ni ó lé e jáde,
gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ tí afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn fẹ́.
9Nítorí èyí báyìí ni ètùtù yóò ṣe wà
fún ẹ̀ṣẹ̀ Jakọbu,
èyí ni yóò sì jẹ́ èso kíkún ti
ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ rẹ.
Nígbà tí ó bá mú kí àwọn òkúta pẹpẹ
dàbí òkúta ẹfun tí a fọ́ sí wẹ́wẹ́,
kì yóò sí ère Aṣerah tàbí pẹpẹ tùràrí
tí yóò wà ní ìdúró.
10Ìlú olódi náà ti dahoro,
ibùdó ìkọ̀sílẹ̀, tí a kọ̀ tì
gẹ́gẹ́ bí aginjù;
níbẹ̀ ni àwọn ọmọ màlúù ti ń jẹ oko
níbẹ̀ ni wọn ń sùn sílẹ̀;
wọn sì jẹ gbogbo ẹ̀ka rẹ̀ tán.
11Nígbà tí àwọn ẹ̀ka rẹ̀ bá rọ, a ó ya wọn dànù
àwọn obìnrin dé, wọ́n sì fi wọ́n dáná
nítorí aláìlóye ènìyàn ni wọn jẹ́,
nítorí náà ni ẹni tí ó dá wọn kì yóò ṣàánú fún wọn;
bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó mọ wọn kì yóò sì fi ojúrere wò wọ́n.
12Ní ọjọ́ náà Olúwa yóò sì kó oore láti ìṣàn omi odo Eufurate wá títí dé Wadi ti Ejibiti, àti ìwọ, ìwọ ọmọ Israẹli, ni a ó kójọ ní ọ̀kọ̀ọ̀kan. 1327.13: Mt 24.31; 1Kọ 15.52; 1Tẹ 4.16.Àti ní ọjọ́ náà, a ó fun fèrè ńlá kan. Gbogbo àwọn tí ń ṣègbé lọ ní Asiria àti àwọn tí ń ṣe àtìpó ní Ejibiti yóò wá sin Olúwa ní òkè mímọ́ ní Jerusalẹmu.