ሕዝቅኤል 7 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

ሕዝቅኤል 7:1-27

ፍጻሜው ደረሰ

1የእግዚአብሔር ቃል እንዲህ ሲል ወደ እኔ መጣ፤ 2“አንተ የሰው ልጅ ሆይ፤ ጌታ እግዚአብሔር ለእስራኤል ምድር እንዲህ ይላል፤

“ ‘ፍጻሜ! በአራቱም የምድሪቱ ማእዘን

ፍጻሜ መጥቷል!

3አሁንም መጨረሻሽ ደርሷል፤

ቍጣዬን በአንቺ ላይ አፈስሳለሁ፤

እንደ አካሄድሽ እፈርድብሻለሁ፤

ስለ ጸያፍ ተግባርሽ ሁሉ፣

ተገቢውን ቅጣት እከፍልሻለሁ።

4በርኅራኄ ዐይን አልመለከትሽም፤

ምሕረትም አላደርግልሽም፤

ስለ አካሄድሽና በመካከልሽ ስላለው ጸያፍ ተግባር፣

ተገቢውን ቅጣት እከፍልሻለሁ፤

በዚያ ጊዜ እኔ እግዚአብሔር እንደ ሆንሁ ታውቃላችሁ።’

5“ጌታ እግዚአብሔር እንዲህ ይላል፤

“ ‘መዓት! ተሰምቶ የማይታወቅ መዓት7፥5 አብዛኛዎቹ የዕብራይስጥ የጥንት ቅጆች እንዲሁ ናቸው፤ አንዳንድ የዕብራይስጥና የሱርስት የጥንት ቅጆች ግን በጥፋት ላይ ጥፋት ይላሉ ይመጣል።

6ፍጻሜ መጥቷል!

ፍጻሜ መጥቷል!

በአንቺ ላይ ተነሣሥቷል፤

እነሆ፤ ደርሷል!

7እናንት በምድሪቱ የምትኖሩ ሆይ፤

የጥፋት ፍርድ መጥቶባችኋል፤

ጊዜው ደርሷል፤

በተራሮች ላይ እልልታ ሳይሆን ሽብር የሚሰማበት ቀን ቀርቧል።

8እነሆ፤ መዓቴን በቅርብ ቀን አፈስስብሻለሁ፤

በአንቺ ላይ ቍጣዬን እፈጽምብሻለሁ፤

እንደ አካሄድሽ እፈርድብሻለሁ፤

ስለ ጸያፍ ተግባርሽም ሁሉ ተገቢውን ቅጣት እከፍልሻለሁ።

9በርኅራኄ ዐይን አልመለከትሽም፤

ምሕረት አላደርግልሽም፤

ስለ አካሄድሽና በመካከልሽ ስላለው ጸያፍ ተግባር፣

ተገቢውን ቅጣት እከፍልሻለሁ፤

በዚያ ጊዜ፣ የምቀሥፍ እኔ እግዚአብሔር መሆኔን ታውቃላችሁ።

10“ ‘እነሆ ቀኑ ይኸው ደረሰ!

የጥፋት ፍርድ ተገልጧል፤

በትሩ አቈጥቍጧል፤

ትዕቢት አብቧል።

11ዐመፅ ዐድጋ7፥11 ወይም ዐመፀኛው የክፋት በትር

የክፋት በትር ሆነች፤

ከሕዝቡ አንድም አይተርፍም፤

ከሰዎቹ፣

ከሀብታቸውና እርባና ካለው ነገር

አንዳች አይቀርም።

12ጊዜው ደርሷል፤

ቀኑም ይኸው!

መዓት በሕዝቡ ሁሉ ላይ ስለ መጣ፣

የሚገዛ አይደሰት፤

የሚሸጥም አይዘን።

13ሁለቱ በሕይወት እስካሉ ድረስ

ሻጩ የሸጠውን መሬት አያስመልስም፤

ስለ መላው ሕዝብ የተነገረው ራእይ አይለወጥምና።

ከኀጢአታቸው የተነሣ ሕይወቱን ማትረፍ የሚችል አንድም አይገኝም።

14“ ‘መለከት ቢነፉም፣

ሁሉንም ነገር ቢያዘጋጁም፣

ወደ ጦርነት የሚሄድ አንድ እንኳ አይኖርም፤

መዓቴ በሕዝብ ሁሉ ላይ መጥቷልና።

15በውጭ ሰይፍ፣

በውስጥ ደግሞ ቸነፈርና ራብ አለ፤

በገጠር ያሉት

በሰይፍ ይወድቃሉ፤

በከተማ ያሉትም

በራብና በቸነፈር ያልቃሉ።

16ተርፈው ያመለጡት ሁሉ

በሸለቆ እንደሚኖሩ ርግቦች

ስለ ኀጢአታቸው እያለቀሱ

በተራራ ላይ ይሆናሉ።

17እጅ ሁሉ ይዝላል፤

ጕልበት ሁሉ ውሃ ይሆናል።

18ማቅ ይለብሳሉ፤

ሽብርም ይውጣቸዋል።

ፊታቸው ኀፍረት ይለብሳል፤

ራሳቸውም ይላጫል።

19“ ‘ብራቸውን በየጐዳናው ይጥላሉ፤

ወርቃቸውም እንደ ርኩስ ነገር ይቈጠራል።

በእግዚአብሔር የቍጣ ቀን

ብራቸውና ወርቃቸው

ሊያድናቸው አይችልም፤

በኀጢአት እንዲወድቁ ዕንቅፋት ሆኖባቸዋልና

በልተው አይጠግቡበትም፤ ሆዳቸውንም አይሞሉበትም።

20በውብ ዕንቋቸው ታብየዋል፤

ይህንም አስጸያፊ የጣዖት ምስሎቻቸውንና

ርኩስ ቅርጻ ቅርጾችን ለመሥራት ተጠቅመውበታል።

ስለዚህ እነዚህን ነገሮች ወደ ርኩሰት እለውጥባቸዋለሁ።

21ለባዕዳን ዝርፊያ፣ ለምድር ክፉዎችም ብዝበዛ አድርጌ አሳልፌ እሰጣለሁ፤

እነርሱም ያረክሱታል።

22ፊቴን ከእነርሱ እመልሳለሁ፤

እነርሱም የከበረውን ቦታዬን ያረክሳሉ፤

ወንበዴዎች ይገቡበታል፤

ያረክሱታልም።

23“ ‘ምድር በደም መፋሰስ፣

ከተማዪቱም በዐመፅ ተሞልታለችና

ሰንሰለት አዘጋጅ።

24እጅግ የከፉትን ከአሕዛብ አምጥቼ

ቤቶቻቸውን እንዲነጥቁ አደርጋለሁ፣

የኀያላኑንም ትዕቢት አጠፋለሁ፤

መቅደሳቸውም ይረክሳል።

25ሽብር በመጣ ጊዜ ሰላምን ይሻሉ፤

ነገር ግን አያገኟትም።

26ጥፋት በጥፋት ላይ፣

ወሬም በወሬ ላይ ይመጣል።

ራእይን ከነቢይ ለማግኘት ይጥራሉ፤

የሕግ ትምህርት ከካህኑ፣

ምክርም ከሽማግሌው ዘንድ ይጠፋል።

27ንጉሡ ያለቅሳል፤

መስፍኑ ተስፋ መቍረጥን ይከናነባል፤

የምድሪቱም ሕዝብ እጅ ትንቀጠቀጣለች።

የእጃቸውን እከፍላቸዋለሁ፤

ራሳቸው ባወጡት መስፈርት መሠረት

እፈርድባቸዋለሁ።

በዚያ ጊዜ እኔ እግዚአብሔር እንደ ሆንሁ ያውቃሉ።’ ”

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Esekiẹli 7:1-27

Òpin ti dé

1Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá: 27.2: If 7.1; 20.8.“Ọmọ ènìyàn, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí sí ilé Israẹli:

“ ‘Òpin! Òpin ti dé

sí igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin ilẹ̀ náà!

3Òpin tí dé sí ọ báyìí,

èmi yóò sì tú ìbínú mi jáde sí ọ,

èmi yóò dájọ́ rẹ gẹ́gẹ́ bí ìwà rẹ,

èmi yóò sì san án fún ọ gẹ́gẹ́ bí gbogbo ìwà ìríra rẹ.

4Ojú mi kò ní i dá ọ sì,

bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò ṣàánú;

ṣùgbọ́n èmi yóò san án fún ọ gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ

àti gbogbo ìwà ìríra tó wà láàrín rẹ.

Nígbà náà ní ẹ̀yin yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.’

5“Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí:

“ ‘Ibi! Ibi kan ṣoṣo.

Kíyèsi, ó bọ̀ ní orí rẹ!

6Òpin ti dé!

Òpin ti dé!

Ó ti dìde lòdì sí ọ.

Kíyèsi, ó ti dé!

7Ìparun ti dé sórí rẹ,

ìwọ tó ń gbé ní ilẹ̀ náà.

Àkókò náà dé! Ọjọ́ wàhálà ti súnmọ́ etílé!

Kì í ṣe ọjọ́ ariwo ayọ̀ lórí òkè.

8Mo ṣetán láti tú ìbínú gbígbóná mi lé ọ lórí

àti láti lo ìbínú mi lórí rẹ gẹ́gẹ́ bí gbogbo ọ̀nà rẹ,

èmi yóò sì dá ọ lẹ́jọ́ gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ

àti gẹ́gẹ́ bí ìwà ìríra rẹ ni èmi yóò sì san án fún ọ.

9Ojú mi kò ní i dá ọ sí,

Èmi kò sì ní wò ọ́ pẹ̀lú àánú;

èmi yóò san án fún ọ gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ

àti fún gbogbo ìwà ìríra tí wà láàrín rẹ.

“ ‘Nígbà náà ní ẹ o mọ̀ pé Èmi Olúwa lo kọlù yín.

10“ ‘Ọjọ́ náà dé!

Kíyèsi ó ti dé!

Ìparun ti bú jáde,

ọ̀pá ti tanná,

ìgbéraga ti rúdí!

11Ìwà ipá ti di ọ̀pá ìwà búburú;

ọ̀pá láti jẹ ẹni búburú ní ìyà.

Kò sí nínú wọn tí yóò ṣẹ́kù,

tàbí nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn,

kò sí nínú ọrọ̀ wọn,

kò sí ohun tí ó ní iye.

12Àkókò náà dé!

Ọjọ́ náà ti dé!

Kí òǹrajà má ṣe yọ̀,

bẹ́ẹ̀ ni ki òǹtajà má ṣe ṣọ̀fọ̀;

nítorí, ìbínú gbígbóná wà lórí gbogbo ènìyàn.

13Nítorí pé òǹtajà kì yóò rí gbà padà

dúkìá èyí tó tà

níwọ̀n ìgbà ti àwọn méjèèjì bá wà láààyè.

Nítorí ìran tó kan gbogbo ènìyàn yìí

kò ní yí padà.

Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn, kò sí ọ̀kan nínú wọn

tí yóò gba ara rẹ̀ là.

14“ ‘Wọ́n ti fọn ìpè ogun,

tí wọ́n sì pèsè ohun gbogbo sílẹ̀,

ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí yóò lọ ojú ogun,

nítorí ìbínú gbígbóná mi ti wà lórí gbogbo ènìyàn.

15Idà wà ní ìta,

àjàkálẹ̀-ààrùn àti ìyàn wà nílé,

idà yóò pa ẹni tó bá wà ní orílẹ̀-èdè,

àjàkálẹ̀-ààrùn àti ìyàn yóò pa ẹni tó bá wà ní ìlú.

16Gbogbo àwọn tí ó bọ́ nínú wọn yóò sálà,

wọn yóò sì wà lórí òkè.

Bí i àdàbà inú àfonífojì,

gbogbo wọn yóò máa ṣọ̀fọ̀,

olúkúlùkù nítorí àìṣedéédéé rẹ̀.

17Gbogbo ọwọ́ yóò rọ,

gbogbo orúnkún yóò di aláìlágbára bí omi.

18Wọn yóò wọ aṣọ ọ̀fọ̀,

ẹ̀rù yóò sì bò wọ́n mọ́lẹ̀,

ìtìjú yóò mù wọn,

wọn yóò sì fá irun wọn.

19“ ‘Wọn yóò dà fàdákà wọn sí ojú pópó,

wúrà wọn yóò sì dàbí èérí

fàdákà àti wúrà wọn

kò ní le gbà wọ́n

ní ọjọ́ ìbínú gbígbóná Olúwa.

Wọn kò ní le jẹun tẹ́ ra wọn lọ́rùn

tàbí kí wọn kún ikùn wọn pẹ̀lú oúnjẹ

nítorí pé ó ti di ohun ìkọ̀sẹ̀ fún wọn.

20Wọ́n ń ṣe ìgbéraga pẹ̀lú ohun ọ̀ṣọ́ wọn tí ó lẹ́wà,

wọn sì ti fi ṣe òrìṣà,

wọn sì tún ya àwòrán ìríra wọn níbẹ̀.

Nítorí náà, èmi yóò sọ àwọn nǹkan wọ̀nyí di aláìmọ́ fún wọn.

21Èmi yóò sì fi àwọn nǹkan wọ̀nyí ṣe ìjẹ fún àjèjì

àti ìkógun fún àwọn ènìyàn búburú ayé,

wọn yóò sì sọ ọ́ di aláìmọ́.

22Èmi yóò gbójú mi kúrò lára wọn,

àwọn ọlọ́ṣà yóò sì sọ ibi ìṣúra mi di aláìmọ́;

àwọn ọlọ́ṣà yóò wọ inú rẹ̀,

wọn yóò sì bà á jẹ́.

23“ ‘Rọ ẹ̀wọ̀n irin!

Nítorí pé ilẹ̀ náà kún fún ẹ̀ṣẹ̀ ìtàjẹ̀ sílẹ̀,

ìlú náà sí kún fún ìwà ipá.

24Èmi yóò mú kí orílẹ̀-èdè ti ó búburú jùlọ

láti jogún ilé wọn.

Èmi yóò sì fi òpin sí ìgbéraga àwọn alágbára,

ibi mímọ́ wọn yóò sì di bíbàjẹ́.

25Nígbà tí ìpayà bá dé,

wọn yóò wá àlàáfíà, lórí asán.

26Wàhálà lórí wàhálà yóò dé,

ìdágìrì lórí ìdágìrì.

Nígbà náà ni wọn yóò wá ìran lọ́dọ̀ wòlíì,

ṣùgbọ́n ẹ̀kọ́ òfin yóò parun lọ́dọ̀ àlùfáà,

bẹ́ẹ̀ ni ìmọ̀ràn yóò ṣègbé lọ́dọ̀ àwọn àgbàgbà.

27Ọba yóò ṣọ̀fọ̀,

ọmọ-aládé yóò wà láìní ìrètí,

ọwọ́ àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà yóò wárìrì.

Èmi yóò ṣe é fún wọn gẹ́gẹ́ bí ìṣe wọn,

èmi yóò ṣe ìdájọ́ wọn gẹ́gẹ́ bí ìgbékalẹ̀ wọn.

Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé èmi ní Olúwa.’ ”