民数記 12 – JCB & YCB

Japanese Contemporary Bible

民数記 12:1-16

12

ミリヤムとアロンの反抗

1ある日、ミリヤムとアロンは、モーセの妻がクシュ人だということで彼を非難しました。 2「主のことばを伝えるのはモーセだけじゃない。私たちだって、ちゃんと話ができるのではないか。」

3-4このことを聞いた主は、さっそくモーセとアロンとミリヤムを幕屋に呼びました。「三人ともここに来なさい。」

言われるままに彼らは、主の前に出ました。モーセはだれよりも謙遜な人でした。

5それから、主は雲に身を隠して降りて来て、幕屋の入口に立って命じました。「アロンとミリヤム、前に出なさい。」二人は言われたとおりにしました。 6「わたしは預言者には幻や夢の中で話をするが、 7-8モーセはそうではない。彼はいつでもわたしと会って、直接話ができる。わたしの姿も見ることができる。それなのになぜ、恐れもなく彼を非難するのか。」

9主は激しく二人をしかり、立ち去りました。 10そして、雲が幕屋を離れると、そのとたんミリヤムはツァラアトにかかり、見る見る肌が白くなっていきました。 11それを見たアロンは必死で叫びました。「ああ、モーセ。赦してくれ! あんな愚かなことを言って悪かった。 12ミリヤムを、肉が腐りかかった死産の子のようにしないでくれ。」

13モーセは祈りました。「神様! どうか姉を治してやってください。」

14しかし、主は答えました。「父親が娘の顔につばをしてさえ、娘は七日間汚れるではないか。ミリヤムを野営地の外に出しなさい。七日たったら連れ戻してもよい。」

15それでミリヤムは宿営の外に締め出され、一週間、イスラエル人は彼女が戻るまで旅に出ませんでした。 16そのあと彼らはハツェロテを去り、パランの荒野に野営することになりました。

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Numeri 12:1-16

Miriamu Àti Aaroni tako Mose

1Miriamu àti Aaroni sọ̀rọ̀-òdì sí Mose nítorí pé ó fẹ́ obìnrin ará Etiopia. 2Wọ́n sì wí pé, “Nípa Mose nìkan ni Olúwa ti sọ̀rọ̀ bí, kò ha ti ipa wa sọ̀rọ̀ bí?” Olúwa sì gbọ́ èyí.

3(Mose sì jẹ́ ọlọ́kàn tútù ju gbogbo ènìyàn tó wà lórí ilẹ̀ ayé lọ).

4Lẹ́ẹ̀kan náà ni Olúwa sọ fún Mose, Aaroni àti Miriamu pé, “Ẹ̀yin mẹ́tẹ̀ẹ̀ta, jáde wá sínú àgọ́ ìpàdé.” Àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sì jáde síta. 5Nígbà náà ni Olúwa sọ̀kalẹ̀ nínú ọ̀wọ́n ìkùùkuu, ó sì dúró ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́, ó ké sí Aaroni àti Miriamu. Àwọn méjèèjì sì bọ́ síwájú, 6Ó wí pé, “Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ mi,

“Bí wòlíì Olúwa bá wà láàrín yín,

Èmi Olúwa a máa fi ara à mi hàn án ní ojúran,

Èmi a máa bá a sọ̀rọ̀ nínú àlá.

712.7: Hb 3.2,5,6.Ṣùgbọ́n èyí kò rí bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú Mose ìránṣẹ́ mi;

ó jẹ́ olóòtítọ́ nínú gbogbo ilé mi.

812.8: El 33.11; De 34.10.Mo sì ń bá a sọ̀rọ̀ ní ojúkojú,

ọ̀rọ̀ yékéyéké tí kì í ṣe òwe,

ó rí àwòrán Olúwa.

Kí ló wá dé tí ẹ̀yin kò ṣe bẹ̀rù

láti sọ̀rọ̀-òdì sí Mose ìránṣẹ́ mi?”

9Ìbínú Olúwa sì ru sókè sí wọn Olúwa sì fi wọ́n sílẹ̀.

10Nígbà tí ìkùùkuu kúrò lórí àgọ́ lójijì ni Miriamu di adẹ́tẹ̀, ó funfun bí i yìnyín. Aaroni sì padà wo Miriamu ó sì rí i pé ó ti di adẹ́tẹ̀, 11Aaroni sì wí fún Mose pé, “Jọ̀wọ́ olúwa mi, má ṣe ka ẹ̀ṣẹ̀, èyí tí a fi ìwà òmùgọ̀ dá sí wa lọ́rùn. 12Má ṣe jẹ́ kí ó dàbí òkú ọmọ tí a bí, tí ìdajì ara rẹ̀ ti rà dànù.”

13Torí èyí Mose sì kígbe sí Olúwa, “Ọlọ́run, jọ̀wọ́, mú un láradá!”

1412.14: Nu 5.2,3.Olúwa sì dá Mose lóhùn, “Bí baba rẹ̀ bá tutọ́ sí i lójú, ojú kò wa ní í tì í fún ọjọ́ méje? Dá a dúró sí ẹ̀yìn ibùdó fún ọjọ́ méje, lẹ́yìn èyí ki a tó ó le mú wọlé.” 15Miriamu sì dúró sí ẹ̀yìn ibùdó fún ọjọ́ méje, àwọn ènìyàn kò sì tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò wọn títí tí Miriamu fi wọ inú ibùdó padà.

16Lẹ́yìn èyí, àwọn ènìyàn kúrò ní Haserotu, wọ́n sì pa ibùdó sí aginjù Parani.