Nnwom 15 – AKCB & YCB

Akuapem Twi Contemporary Bible

Nnwom 15:1-5

Dwom 15

Dawid dwom.

1Awurade, hena na ɔbɛtena wo kronkronbea ntamadan no mu?

Hena na ɔbɛtena wo bepɔw kronkron no so?

2Nea ne ho nni asɛm

na ɔyɛ nea ɛteɛ,

nea ɔka nokware a efi ne koma mu

3na ɔmfa ne tɛkrɛma nsɛe nnipa

nea ɔnyɛ ne yɔnko bɔne

na ommu ne yɔnko nipa abomfiaa,

4nea obu afideyɛni animtiaa

na ɔde nidi ma wɔn a wosuro Awurade,

nea odi ne ntam so,

bere a etia no mpo,

5nea ɔde ne sika bɔ bosea a onnye nsiho

na onnye adanmude ntia nea odi bem.

Nea ɔyɛ eyinom no

renhinhim da.

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 15:1-5

Saamu 15

Saamu ti Dafidi.

1Olúwa, ta ni yóò máa ṣe àtìpó nínú àgọ́ rẹ?

Ta ni yóò máa gbé ní òkè mímọ́ rẹ?

2Ẹni tí ń rìn déédé

tí ó sì ń sọ òtítọ́,

láti inú ọkàn rẹ̀;

3tí kò fi ahọ́n rẹ̀ sọ̀rọ̀ ẹni lẹ́yìn,

tí kò ṣe ibi sí aládùúgbò rẹ̀

tí kò sì sọ̀rọ̀ ẹ̀gàn sí ẹnìkejì rẹ̀,

4ní ojú ẹni tí ènìyànkénìyàn di gígàn

ṣùgbọ́n ó bọ̀wọ̀ fún àwọn tí ó bẹ̀rù Olúwa,

ẹni tí ó búra sí ibi ara rẹ̀

àní tí kò sì yípadà,

5tí ó ń yá ni lówó láìsí èlé

tí kò sì gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ lòdì sí aláìlẹ́ṣẹ̀.

Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe èyí

ni a kì yóò mì láéláé.