Saamu 136 – YCB & AKCB

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 136:1-26

Saamu 136

1Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí tí ó ṣeun;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

2Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run àwọn ọlọ́run:

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

3Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa àwọn olúwa,

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

4Fún Òun nìkan tí ń ṣiṣẹ́ ìyanu ńlá;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

5Fún ẹni tí ó fi ọgbọ́n dá ọ̀run;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

6136.6: Gẹ 1.2.Fún ẹni tí ó tẹ́ ilẹ̀ lórí omi;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

7136.7-9: Gẹ 1.16.Fún ẹni tí ó dá àwọn ìmọ́lẹ̀ ńlá;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

8Òòrùn láti jẹ ọba ọ̀sán;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

9Òṣùpá àti ìràwọ̀ láti jẹ ọba òru;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

10136.10: Ek 12.29.Fún ẹni tí ó kọlu Ejibiti lára àwọn àkọ́bí wọn;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

11136.11: Ek 12.51.Ó sì mú Israẹli jáde kúrò láàrín wọn;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

12Pẹ̀lú ọwọ́ agbára àti apá nínà;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

13136.13-15: Ek 14.21-29.Fún ẹni tí ó pín Òkun pupa ní ìyà;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

14Ó sì mú Israẹli kọjá láàrín rẹ̀

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

15Ṣùgbọ́n ó bi Farao àti ogun rẹ̀ ṣubú nínú Òkun pupa;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

16Fún ẹni tí ó sin àwọn ènìyàn rẹ̀ la aginjù já

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

17Fún ẹni tí ó kọlu àwọn ọba ńlá;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

18Ó sì pa àwọn ọba olókìkí

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

19Sihoni, ọba àwọn ará Amori

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

20Àti Ogu, ọba Baṣani;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

21Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní,

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

22Ìní fún Israẹli, ìránṣẹ́ rẹ̀,

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

23Ẹni tí ó rántí wa ní ìwà ìrẹ̀lẹ̀ wa;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

24Ó sì dá wa ní ìdè lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

25Ẹni tí ó fi oúnjẹ fún àwọn ẹ̀dá gbogbo

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

26Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run ọ̀run;

nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

Akuapem Twi Contemporary Bible

Nnwom 136:1-26

Dwom 136

1Monna Awurade ase na oye.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

2Monna anyame mu Nyankopɔn no ase.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

3Monna awuranom mu Awurade no ase.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

4Ɔno nko ara na ɔyɛ anwonwade akɛse.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

5Ɔno na ofi ne ntease mu bɔɔ ɔsoro.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

6Ɔno na ɔtrɛw asase mu de kataa nsu so.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

7Ɔno na ɔbɔɔ akanea akɛse no.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

8Ɔbɔɔ owia sɛ enni adekyee so.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa;

9Ɔbɔɔ sram ne nsoromma sɛ wonni adesae so no.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

10Ɔno na okunkum Misraimfo mmakan,

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

11na oyii Israelfo fii wɔn mu no.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

12Ɔde nsa kɛse ne basa a wateɛ mu.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

13Ɔno na ɔpaee Po Kɔkɔɔ no mu no,

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

14na ɔde Israelfo faa mfimfini no.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

15Nanso ɔpraa Farao ne nʼasraafo guu Po Kɔkɔɔ mu no.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

16Ɔno na odii ne nkurɔfo anim wɔ sare no so.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

17Ɔno na okum ahemfo akɛse no,

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

18na okum ahemfo akunini no.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

19Okum Amorifo hene, Sihon,

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

20ne Basanhene, Og.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

21Na ɔde wɔn nsase maa sɛ agyapade.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

22Ɔde maa ne somfo Israel sɛ agyapade.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

23Ɔkaee yɛn, yɛn mmerɛwyɛ mu.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

24Na ogyee yɛn fii yɛn atamfo nsam.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

25Ɔno na ɔma abɔde biara aduan.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.

26Monna ɔsorosoro Nyankopɔn no ase.

Nʼadɔe wɔ hɔ daa.