Mika 1 – YCB & GKY

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Mika 1:1-16

1Ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Mika ará Moreṣeti wá ní àkókò ìjọba Jotamu, Ahasi, àti Hesekiah, àwọn ọba Juda nìwọ̀nyí, ìran tí ó rí nípa Samaria àti Jerusalẹmu.

2Ẹ gbọ́, gbogbo ẹ̀yin ènìyàn,

fetísílẹ̀, ìwọ ayé àti gbogbo ohun tó wà níbẹ̀,

Olúwa Olódùmarè lè ṣe ẹlẹ́rìí sí yín,

1.2: 1Ọb 22.28.Olúwa láti inú tẹmpili mímọ́ rẹ̀ wá.

Ìdájọ́ tí o lòdì sí Samaria àti Jerusalẹmu

3Wò ó! Olúwa ń bọ̀ wá láti ibùgbé rẹ̀;

yóò sọ̀kalẹ̀, yóò sì tẹ ibi gíga ayé mọ́lẹ̀.

4Àwọn òkè ńlá yóò sí yọ́ lábẹ́ rẹ̀,

àwọn Àfonífojì yóò sì pínyà,

bí idà níwájú iná,

bí omi tí ó ń sàn lọ ni ibi gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́.

5Nítorí ìré-òfin-kọjá Jakọbu ni gbogbo èyí,

àti nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ilé Israẹli.

Kí ni ìré-òfin-kọjá Jakọbu?

Ǹjẹ́ Samaria ha kọ?

Kí ni àwọn ibi gíga Juda?

Ǹjẹ́ Jerusalẹmu ha kọ?

6“Nítorí náà, èmi yóò ṣe Samaria bí òkìtì lórí pápá,

bí ibi ti à ń lò fún gbígbin ọgbà àjàrà.

Èmi yóò gbá àwọn òkúta rẹ̀ dànù sínú àfonífojì.

Èmi yóò sí tú ìpilẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ palẹ̀.

7Gbogbo àwọn ère fínfín rẹ̀ ni a ó fọ́ sí wẹ́wẹ́

gbogbo àwọn ẹ̀bùn tẹmpili rẹ̀ ni a ó fi iná sun:

Èmi yóò sì pa gbogbo àwọn òrìṣà rẹ̀ run.

Nítorí tí ó ti kó àwọn ẹ̀bùn rẹ̀ jọ láti inú owó èrè panṣágà,

gẹ́gẹ́ bí owó èrè panṣágà, wọn yóò sì tún padà sí owó iṣẹ́ panṣágà.”

Ẹkún òun ọfọ̀

8Nítorí èyí, èmi yóò sì sọkún,

èmi yóò sì pohùnréré ẹkún:

èmi yóò máa lọ ní ẹsẹ̀ lásán àti ní ìhòhò

Èmi yóò ké bí akátá,

èmi yóò sì máa dárò bí àwọn ọmọ ògòǹgò.

9Nítorí tí ọgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláìlèwòtán;

ó sì ti wá sí Juda.

Ó sì ti dé ẹnu-bodè àwọn ènìyàn mi,

àní sí Jerusalẹmu.

10Ẹ má ṣe sọ ní Gati

ẹ má ṣe sọkún rárá.

Ní ilẹ̀ Beti-Ofra

mo yí ara mi nínú eruku.

11Ẹ kọjá lọ ni ìhòhò àti ni ìtìjú,

ìwọ tí ó ń gbé ni Ṣafiri.

Àwọn tí ó ń gbé ni Ṣaanani

kì yóò sì jáde wá.

Beti-Eseli wà nínú ọ̀fọ̀;

A ó sì gba ààbò rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ yin.

12Nítorí àwọn tí ó ń gbé ni Marati ń retí ìre,

Ṣùgbọ́n ibi sọ̀kalẹ̀ ti ọ̀dọ̀ Olúwa wá sí ẹnu-bodè Jerusalẹmu.

13Ìwọ olùgbé Lakiṣi,

dì kẹ̀kẹ́ mọ́ ẹranko tí ó yára.

Òun sì ni ìbẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣẹ̀

sí àwọn ọmọbìnrin Sioni,

nítorí a rí àìṣedéédéé Israẹli nínú rẹ̀.

14Nítorí náà ni ìwọ ó ṣe fi ìwé ìkọ̀sílẹ̀

fún Moreṣeti Gati.

Àwọn ilé Aksibu yóò jẹ́ ẹlẹ́tàn sí àwọn ọba Israẹli.

15Èmi yóò sì mú àrólé kan wá sórí rẹ ìwọ olùgbé Meraṣa.

Ẹni tí ó jẹ́ ògo Israẹli

yóò sì wá sí Adullamu.

16Fá irun orí rẹ nínú ọ̀fọ̀

nítorí àwọn ọmọ rẹ aláìlágbára,

sọ ra rẹ̀ di apárí bí ẹyẹ igún,

nítorí wọn yóò kúrò lọ́dọ̀ rẹ lọ sí ìgbèkùn.

Holy Bible in Gĩkũyũ

Mika 1:1-16

11:1 Jer 26:18; 1Maũ 3:13Ĩno nĩyo ndũmĩrĩri ya Jehova ĩrĩa yakinyĩrĩire Mika1:1 Rĩĩtwa Mika rĩgĩtaũrwo nĩ kuuga “Nũũ ũhaana ta Jehova”. ũrĩa warĩ wa itũũra rĩa Moreshethu, ĩkoniĩ Samaria na Jerusalemu, hĩndĩ ya ũthamaki wa Jothamu, na wa Ahazu, na wa Hezekia, athamaki a Juda.

21:2 Gũcook 32:1; Jer 6:19Atĩrĩrĩ, ta thikĩrĩriai inyuĩ andũ aya inyuothe;

o nawe thĩ ta igua, na arĩa othe matũũraga kuo,

nĩgeetha Mwathani Jehova arute ũira wa kũmũũkĩrĩra,

o we Mwathani arĩ thĩinĩ wa hekarũ yake theru.

Ituĩro rĩa Gũũkĩrĩra Samaria na Jerusalemu

31:3 Amos 4:13Atĩrĩrĩ! Jehova nĩarooka oimĩte gĩikaro gĩake;

araikũrũka arangĩrĩrie kũrĩa gũtũũgĩru gũkũ thĩ.

41:4 Ayub 9:5; Nahu 1:5Irĩma itwekaga irĩ rungu rwake,

nayo mĩkuru ĩgaatũkana;

itwekaga ta mũhũra ũrĩ mwaki-inĩ,

igaikũrũka ta maaĩ maikũrũkĩte na ihenya kĩgaragaro-inĩ.

5Ũndũ ũyũ wonekete nĩ ũndũ wa ũremi wa Jakubu,

na nĩ ũndũ wa mehia ma nyũmba ya Isiraeli.

Ũremi wa Jakubu-rĩ, nĩ ũrĩkũ?

Githĩ ti Samaria?

Kũndũ kũrĩa gũtũũgĩru kwa Juda-rĩ, nĩ kũ?

Githĩ ti Jerusalemu?

61:6 Amos 5:11; Ezek 13:14“Nĩ ũndũ ũcio, ngaatua Samaria hĩba ya mahiga,

gũtuĩke kũndũ gwa kũhaandagwo mĩthabibũ.

Nĩngaita mahiga marĩo mũkuru-inĩ

na thikũrie mĩthingi yarĩo.

71:7 Ezek 6:6; Gũcook 9:21Mĩhianano yarĩo yothe nĩĩkoinangwo icunjĩ;

nacio iheo ciothe cia hekarũ yarĩo icinwo na mwaki.

Nĩngananga mĩhianano yothe yarĩo.

Tondũ rĩonganirie iheo ciarĩo kuuma mũcaara wa ũmaraya,

na igaatũmĩrwo rĩngĩ irĩ mũcaara wa kũrĩha maraya.”

Maithori na Kĩrĩro

81:8 Isa 15:3Tondũ ũcio-rĩ, ngũrĩra na ngirĩke,

na thiĩ ndĩ magũrũ matheri na ndĩ njaga.

Ngũgirĩka o ta mbwe,

na ndĩre ta ndundu.

91:9 2Ath 18:13; Isa 3:26Nĩgũkorwo kĩronda kĩarĩo gĩtingĩhona;

gĩũkĩte gĩgakinya Juda.

Nĩgĩkinyĩte o kĩhingo‑inĩ kĩa andũ akwa,

gĩgakinya Jerusalemu kuo kwene.

10Mũtikaheane ũhoro ũcio kũu Gathu,

mũtikarĩre o na hanini.

Ningĩ kũu Bethi-Ofara

mwĩgaragariei rũkũngũ‑inĩ.

111:11 Ezek 23:29Inyuĩ andũ arĩa mũtũũraga Shafiri,

thiĩi mũrĩ njaga na mũconokete.

Andũ arĩa matũũraga Zaanani

matingiuma itũũra rĩao.

Narĩo itũũra rĩa Bethi-Ezeli no gũcaaya rĩracaaya,

itũũra rĩu rĩtingĩhota gũkũgitĩra.

121:12 Jer 14:19Andũ arĩa matũũraga Marothu-rĩ,

menyogondaga nĩ ruo, o metereire ũteithio,

nĩ ũndũ mwanangĩko ũikũrũkĩte kuuma kũrĩ Jehova,

ũgakinya o kĩhingo-inĩ kĩa Jerusalemu.

131:13 Josh 10:3; Thab 9:14Inyuĩ mũtũũraga Lakishi,1:13 Lakishi rĩarĩ itũũra rĩmwe rĩa marĩa manene mũno ma Juda.

ngaari cianyu cia ita ciohererei mbarathi.

Nĩ inyuĩ mwatoonyirie Mwarĩ wa Zayuni mehia-inĩ,

nĩgũkorwo ũremi wa Isiraeli woimanire na inyuĩ.

141:14 Jer 15:18; Josh 15:44Nĩ ũndũ ũcio nĩmũkahe Moreshethu-Gathu

iheo cia kuuganĩra ũhoro.

Itũũra rĩa Akizibu no rĩa kũheenereria

athamaki a Isiraeli.

151:15 Josh 15:44; Josh 12:15Inyuĩ mũtũũraga Maresha

nĩngamũrehithĩria mũndũ wa kũmũũkĩrĩra, amũtoorie.

Ũrĩa we ũrĩ Riiri wa Isiraeli

nĩagooka Adulamu.

161:16 Alaw 13:40; Gũcook 5:27Enjwoi mĩtwe mũcakaĩre

ciana cianyu iria mũkenagĩra;

mwĩenjei kĩhara mũhaane ta nderi,

nĩgũkorwo ciana icio cianyu nĩigatahwo.