Jobu 7 – YCB & AKCB

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Jobu 7:1-21

Jobu ha ni ìrètí bí?

1“Ṣé ìjà kò ha si fún ènìyàn lórí ilẹ̀?

Ọjọ́ rẹ̀ pẹ̀lú kò ha dàbí ọjọ́ alágbàṣe?

2Bí ọmọ ọ̀dọ̀ tí máa ń kánjú bojú wo òjìji,

àti bí alágbàṣe ti í kánjú wo ọ̀nà owó iṣẹ́ rẹ̀.

3Bẹ́ẹ̀ ni a mú mi ní ìbànújẹ́ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ oṣù,

òru ìdáni-lágara ni a sì là sílẹ̀ fún mi.

4Nígbà ti mo dùbúlẹ̀, èmi wí pé, ‘Nígbà wo ni èmi ó dìde?’

Tí òru yóò sì kọjá, ó sì tó fún mi láti yí síhìn-ín yí sọ́hùn-ún, títí yóò fi di àfẹ̀mọ́júmọ́.

5Kòkòrò àti ògúlùtu erùpẹ̀ ni á fi wọ̀ mi ni aṣọ,

awọ ara mi bù, o sì di bíbàjẹ́.

6“Ọjọ́ mi yára jù ọkọ̀ ìhunṣọ lọ,

o sì di lílò ní àìní ìrètí.

7Háà! Rántí pé afẹ́fẹ́ ni ẹ̀mí mi;

ojú mi kì yóò padà rí rere mọ́.

8Ojú ẹni tí ó rí mi, kì yóò rí mi mọ́;

ojú rẹ̀ tẹ̀ mọ́ra mi, èmi kò sí mọ́.

9Bí ìkùùkuu tí i túká, tí í sì fò lọ,

bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ń lọ sí ipò òkú tí kì yóò padà wa mọ́.

10Kì yóò padà sínú ilé rẹ̀ mọ́,

bẹ́ẹ̀ ní ipò rẹ̀ kì yóò mọ̀ ọn mọ́.

11“Nítorí náà èmi kì yóò pa ẹnu mi mọ́,

èmi yóò máa sọ nínú ìrora ọkàn mi,

èmi yóò máa ṣe ìráhùn nínú kíkorò ọkàn mi.

12Èmi a máa ṣe Òkun tàbí ẹ̀mí búburú,

tí ìwọ fi ń yan olùṣọ́ tì mi?

13Nígbà tí mo wí pé, ibùsùn mi yóò tù mí lára,

ìtẹ́ mi yóò mú ara mi fúyẹ́ pẹ̀lú.

14Nígbà náà ni ìwọ fi àlá da yọ mi lénu bò mi,

ìwọ sì fi ìran òru dẹ́rùbà mí.

15Bẹ́ẹ̀ ni ọkàn mí yàn láti fún pa

àti ikú ju kí ń wà láààyè ní ipò tí ara mí wà yìí lọ.

16O sú mi, èmi kò le wà títí:

jọ̀wọ́ mi jẹ́, nítorí pé asán ni ọjọ́ mi.

177.17: Sm 8.4.“Kí ni ènìyàn tí ìwọ o máa kókìkí rẹ̀?

Àti tí ìwọ ìbá fi gbé ọkàn rẹ lé e?

18Àti ti ìwọ ó fi máa wá í bẹ̀ ẹ́ wò ni òròòwúrọ̀,

ti ìwọ o sì máa dán an wò nígbàkúgbà!

19Yóò ti pẹ́ tó kí ìwọ kí ó tó fi mí sílẹ̀ lọ,

tí ìwọ o fi mí sílẹ̀ jẹ́ẹ́ títí èmi yóò fi lè dá itọ́ mi mì.

20Èmi ti ṣẹ̀, ki ní èmi ó ṣe sí ọ.

Ìwọ Olùsójú ènìyàn?

Èéṣe tí ìwọ fi fi mí ṣe ààmì itasi níwájú rẹ,

bẹ́ẹ̀ ni èmi sì di ẹrẹ̀ wíwo fún ọ?

21Èéṣe tí ìwọ kò sì dárí ìrékọjá mi jìn,

kí ìwọ kí ó sì mú àìṣedéédéé mi kúrò?

Ǹjẹ́ nísinsin yìí ni èmi ìbá sùn nínú erùpẹ̀,

ìwọ ìbá sì wá mi kiri ní òwúrọ̀, èmi kì bá tí sí.”

Akuapem Twi Contemporary Bible

Hiob 7:1-21

1“Asase so som nyɛ den mma onipa ana?

Ne nkwanna nte sɛ ɔpaani de?

2Sɛnea akoa ani gyina anwummere sunsuma,

anaasɛ ɔpaani ho pere no nʼakatua ho no,

3saa ara na wɔatwa asram hunu ato me hɔ,

ne anadwo a ɔhaw wɔ mu ama me.

4Sɛ meda a, midwen bisa se, ‘Bere bɛn na ade bɛkye?’

Nanso anadwo twa mu nkakrankakra, na mepere kosi ahemadakye.

5Asunson ne aporɔporɔw afura me nipadua,

me were atetew na ɛrefi nsu.

6“Me nna kɔ ntɛm sen ɔnwemfo akurokurowa,

na ɛkɔ awiei a anidaso biara nni mu.

7Ao, Onyankopɔn, kae sɛ me nkwanna te sɛ ɔhome;

na mʼani renhu anigye bio da.

8Ani a ehu me mprempren no renhu me bio;

mobɛhwehwɛ me, nanso na minni hɔ bio.

9Sɛnea omununkum yera na etu kɔ,

saa ara na nea ɔkɔ ɔda mu no nsan mma bio.

10Ɔrensan mma ne fi da biara da bio;

nʼatenae renkae no bio.

11“Ɛno nti meremmua mʼano;

mifi me honhom ahoyeraw mu akasa,

mefi me kra ɔyaw mu anwiinwii.

12So meyɛ ɛpo anaa aboa kɛse a ɔwɔ bun mu,

na mode me ahyɛ ɔwɛmfo nsa yi?

13Sɛ midwen sɛ minya awerɛkyekye wɔ me mpa so,

na mʼakongua adwudwo mʼanwiinwii ano a,

14ɛno mpo na wode adaeso yi me hu

na wode anisoadehu hunahuna me,

15ɛno nti mepɛ ɔsɛn ne owu,

sen me nipadua yi.

16Mimmu me nkwa; mentena ase afebɔɔ.

Munnyaa me; na me nna nka hwee.

17“Ɔdesani ne hena a ne ho hia wo sɛɛ,

na wʼani ku ne ho,

18na wohwehwɛ ne mu anɔpa biara

na wosɔ no hwɛ bere biara?

19Worennyi wʼani mfi me so da,

anaasɛ worennyaa me bere tiaa bi mpo ana?

20Sɛ mayɛ bɔne a, dɛn na mayɛ wo,

Ao adesamma so wɛmfo?

Adɛn nti na watu wʼani asi me so?

Mayɛ adesoa ama wo ana?

21Adɛn nti na wonkata me mmarato so

na womfa me bɔne nkyɛ me?

Ɛrenkyɛ biara, mɛda mfutuma mu.

Wobɛhwehwɛ me nanso na minni hɔ bio.”