Heberu 1 – YCB & PCB

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Heberu 1:1-14

Ọmọ tí o ṣe pàtàkì fún àwọn Angẹli

1Ní ìgbà àtijọ́, Ọlọ́run bá àwọn baba ńlá wa sọ̀rọ̀ láti ẹnu àwọn wòlíì ní ọ̀pọ̀ ìgbà àti ní onírúurú ọ̀nà, 2ṣùgbọ́n ní ìgbà ìkẹyìn yìí Ọlọ́run ń bá wa sọ̀rọ̀ nípasẹ̀ Ọmọ rẹ̀ Jesu Kristi, ẹni tí ó fi ṣe ajogún ohun gbogbo, nípasẹ̀ ẹni tí ó dá gbogbo ayé yìí àti ohun gbogbo tí ń bẹ nínú rẹ̀: 3Ọmọ tí í ṣe ìtànṣán ògo Ọlọ́run àti àwòrán òun tìkára rẹ̀, tí ó sì ń fi ọ̀rọ̀ agbára rẹ̀ mú ohun gbogbo dúró: Lẹ́yìn tí ó ti ṣe ìwẹ̀nù ẹ̀ṣẹ̀ wa tan, ó wá jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún Ọláńlá ní òkè. 4Nítorí náà, ó sì ti fi bẹ́ẹ̀ di ẹni tí ó ga ní ipò ju angẹli lọ, bí ó ti jogún orúkọ èyí tí ó tayọ̀ tiwọn.

51.5: Sm 2.7; 2Sa 7.14.Nítorí kò sí ọ̀kan nínú àwọn angẹli tí Ọlọ́run fi ìgbà kan sọ fún pé:

“Ìwọ ni ọmọ mi;

lónìí ni mo bí ọ”?

Àti pẹ̀lú pé;

“Èmi yóò jẹ́ baba fún un,

Òun yóò sì jẹ́ ọmọ mi”?

61.6: De 32.43; Sm 97.7.Àti pẹ̀lú, nígbà tí Ọlọ́run rán àkọ́bí rẹ̀ wá si ayé wa yìí. Ó pàṣẹ pé,

“Ẹ jẹ́ kí gbogbo àwọn angẹli Ọlọ́run foríbalẹ̀ fún un.”

71.7: Sm 104.4.Àti nípa ti àwọn angẹli, ó wí pé;

“Ẹni tí ó dá àwọn angẹli rẹ̀ ní ẹ̀mí,

àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ní ọwọ́ iná.”

81.8-9: Sm 45.6-7.Ṣùgbọ́n ó sọ nípa tí Ọmọ rẹ̀ pé,

“Ìtẹ́ rẹ, Ọlọ́run, láé àti láéláé ni,

ọ̀pá aládé òdodo ni ọ̀pá ìjọba rẹ.

9Ìwọ fẹ́ òdodo, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kórìíra iṣẹ́ búburú;

nítorí èyí ni Ọlọ́run, àní Ọlọ́run rẹ ṣe fi ààmì òróró ayọ̀ yàn ọ

tí ó gbé ọ ju àwọn ẹgbẹ́ rẹ lọ.”

10Ó tún sọ pé,

“Ní àtètèkọ́ṣe, ìwọ Olúwa, ìwọ fi ìdí ayé sọlẹ̀,

àwọn ọ̀run sì jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ ara rẹ.

11Wọn yóò ṣègbé, ṣùgbọ́n ìwọ yóò wà síbẹ̀

gbogbo wọn ni yóò di àkísà bí ẹ̀wù.

12Ní kíká ni ìwọ yóò ká wọn bí aṣọ,

bí ìpààrọ̀ aṣọ ni a ó sì pààrọ̀ wọn.

Ṣùgbọ́n ìwọ fúnrarẹ̀ kì yóò yípadà

àti pé ọdún rẹ kì yóò ní òpin.”

131.13: Sm 110.1.Èwo nínú àwọn angẹli ní a gbọ́ pé Ọlọ́run fi ìgbà kan wí fún pé,

“Jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún mi

títí èmi yóò fi sọ àwọn ọ̀tá rẹ

di àpótí ìtìsẹ̀ rẹ”?

14Kì í ha á ṣe ẹ̀mí tí ń jíṣẹ́ ni àwọn angẹli í ṣe bí; tí a rán lọ síta láti máa ṣiṣẹ́ fún àwọn tí yóò jogún ìgbàlà?

Persian Contemporary Bible

عبرانيان 1:1-14

عيسی مسيح فرزند خداست

1در زمانهای گذشته، خدا بوسيلهٔ پيامبران، اراده و مشيت خود را به تدریج بر اجداد ما آشكار می‌فرمود. او از راههای گوناگون، گاه در خواب و رؤيا، گاه حتی روبرو، با پيامبران سخن می‌گفت. 2اما در اين ايام آخر، او توسط فرزندش با ما سخن گفت. خدا در واقع، اختيار همه چيز را به فرزند خود سپرده و جهان و تمام موجودات را به‌وسیله او آفريده است. 3فرزند خدا، منعكس كننده جلال خدا و مظهر دقيق وجود اوست. او با كلام نيرومند خود تمام عالم هستی را اداره می‌كند. او به اين جهان آمد تا جانش را فدا كند و ما را پاک ساخته، گذشتهٔ گناه‌آلود ما را محو نمايد؛ پس از آن، در بالاترين مكان افتخار، يعنی به دست راست خدای متعال نشست.

برتری مسيح بر فرشتگان

4به اين طريق، او از فرشته‌ها برتر گرديد. نام او نيز گواه بر اين برتری است: «پسر خدا!» اين نامی است كه خدای پدر به او داده، و از نام و لقب همه فرشته‌ها بالاتر است؛ 5زيرا خدا خطاب به عيسی فرمود: «تو پسر من هستی؛ امروز اين نام را با تمام افتخاراتش به تو می‌بخشم.» اما دربارهٔ هيچيک از فرشتگان چنين نگفت. در جای ديگری از كتاب آسمانی، خدا فرمود: «من پدر او هستم، و او پسر من است.» 6همچنين، در جای ديگر، هنگامی كه فرزند ارشد او به جهان می‌آمد، فرمود: «همهٔ فرشتگان خدا او را پرستش نمايند!»

7خدا دربارهٔ فرشتگان می‌فرمايد: «همچون باد، به سرعت پيغام می‌برند، و چون شعله‌های آتش، با شور و حرارت خدمت می‌كنند.»

8اما دربارهٔ فرزندش می‌گويد: «ای خدا، سلطنت تو تا ابد برقرار است؛ اساس حكومت تو، بر عدل و راستی است؛ 9راستی را دوست می‌داری، و از ناراستی تنفر داری. بنابراين، خدا، يعنی خدای تو، بيش از هر کس ديگر تو را از شادی لبريز كرده است.»

10خدا همچنين او را «خداوند» ناميده است. از اين جهت در كتاب آسمانی آمده است: «خداوندا، تو در ابتدا زمين را آفريدی، و آسمانها ساختهٔ دستهای توست. 11آنها نيست و نابود خواهند شد، اما تو تا ابد باقی هستی. آنها همچون لباسی كهنه، پوسيده و مندرس خواهند شد؛ 12روزی آنها را در هم خواهی پيچيد و تغيير خواهی داد. اما تو هرگز تغيير نخواهی يافت و سالهای عمر تو پايان نخواهد پذيرفت.»

13خدا به فرزندش فرمود: «در كنار من بنشين تا دشمنانت را زير پايهايت بيفكنم.» اما خطاب به هيچ فرشته‌ای چنين نگفت. 14زيرا فرشته‌ها فقط روح‌هايی خدمتگزار هستند، و برای كمک و مراقبت از كسانی فرستاده می‌شوند كه مايلند نجات الهی را دريافت نمايند.