Gẹnẹsisi 15 – YCB & CARS

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Gẹnẹsisi 15:1-21

Májẹ̀mú Ọlọ́run pẹ̀lú Abramu

1Lẹ́yìn èyí, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Abramu wá lójú ìran pé:

“Abramu má ṣe bẹ̀rù,

Èmi ni ààbò rẹ,

Èmi sì ni èrè ńlá rẹ.”

2Ṣùgbọ́n Abramu wí pé, “Olúwa Olódùmarè, kí ni ìwọ yóò fi fún mi níwọ̀n ìgbà tí èmi kò bímọ, Elieseri ará Damasku ni yóò sì jogún mi,” 3Abramu sì tún tẹ̀síwájú pé, “Ìwọ kò fún mi ní ọmọ, nítorí náà ẹrú nínú ilé mi sì ni yóò jẹ́ àrólé mi.”

415.4: Gẹ 17.16,21; 18.10; 21.2.Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tún tọ̀ ọ́ wá pé: “Ọkùnrin yìí kọ́ ni yóò jẹ́ àrólé rẹ bí kò ṣe ọmọ tí ìwọ bí fúnrarẹ̀ ni yóò jẹ́ àrólé rẹ.” 515.5: Ro 4.18; Hb 11.12.Olúwa sì mú Abramu jáde sí ìta ó sì wí fún un pé, “Gbé ojú sókè sí ọ̀run kí o sì ka àwọn ìràwọ̀ bí ó bá ṣe pé ìwọ le è kà wọ́n.” Ó sì wí fun un pé, “Nítorí náà, báyìí ni irú-ọmọ rẹ yóò rí.”

615.6: Ro 4.3; Ga 3.6; Jk 2.23.Abramu gba Ọlọ́run gbọ́, a sì kà á sí òdodo fún un.

7Ó sì tún wí fún un pé, “Èmi ni Olúwa tí ó mú ọ jáde láti Uri ti Kaldea láti fún ọ ní ilẹ̀ yìí láti jogún.”

8Ṣùgbọ́n Abramu wí pé, “Olúwa Olódùmarè, báwo ni mo ṣe lè mọ̀ pé ilẹ̀ náà yóò jẹ́ ohun ìní mi?”

9Nítorí náà, Olúwa wí fún un pé, “Mú abo màlúù, ewúrẹ́ àti àgbò ọlọ́dún mẹ́ta mẹ́ta wá, àti àdàbà kan àti ọmọ ẹyẹlé kan.”

10Abramu sì mú gbogbo nǹkan wọ̀nyí wá, ó sì là wọ́n sí méjì méjì, ó sì fi ẹ̀là èkínní kọjú sí èkejì, ṣùgbọ́n kò la àwọn ẹyẹ ní tiwọn. 11Àwọn ẹyẹ igún sì ń wá sórí òkú ẹran náà, Abramu sì ń lé wọn.

1215.12: Jb 4.13,14.Bí oòrùn ti ń wọ̀, Abramu sùn lọ fọnfọn, òkùnkùn biribiri tí ó kún fún ẹ̀rù sì bò ó. 1315.13: Ek 1.1-14; Ap 7.6.15.13-14: Ek 12.40,41; Ap 7.7.Nígbà náà ni Olúwa wí fún Abramu pé, “Mọ èyí dájú pé, irú-ọmọ rẹ yóò ṣe àtìpó ní ilẹ̀ àjèjì, wọn ó sì sọ wọn di ẹrú, wọn ó sì pọ́n wọn lójú fún irínwó ọdún (400). 14Ṣùgbọ́n orílẹ̀-èdè náà tí wọn yóò máa sìn, ni èmi ó dá lẹ́jọ́, lẹ́yìn náà ni wọn ó sì jáde pẹ̀lú ọrọ̀ púpọ̀. 15Ṣùgbọ́n ìwọ yóò tọ àwọn baba rẹ lọ ni àlàáfíà, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ yóò sì di arúgbó kí a tó gbé ọ sin. 16Ní ìran kẹrin àwọn ìran rẹ yóò padà wá sí ibi. Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ará Amori kò ì tí ì kún òṣùwọ̀n.”

17Nígbà tí oòrùn wọ̀ tí ilẹ̀ sì ṣú, ìkòkò iná tí ń ṣèéfín àti ọwọ́ iná sì ń kọjá láàrín ẹ̀là ẹran náà. 1815.18: Gẹ 17.2,7,9-14,21.Ní ọjọ́ náà gan an ni Olúwa dá májẹ̀mú pẹ̀lú Abramu, ó sì wí pé, “Àwọn ìran rẹ ni èmi yóò fi ilẹ̀ yìí fún, láti odò Ejibiti dé odò ńlá Eufurate: 19ilẹ̀ àwọn ará Keni, àti ti ará Kenissiti, àti ará Kadmoni, 20àti ti ará Hiti, àti ti ará Peresi, àti ti ará Refaimu. 21Àti ti ará Amori, àti ti ará Kenaani, àti ti ará Girgaṣi àti ti ará Jebusi.”

Священное Писание

Начало 15:1-21

Всевышний заключает священное соглашение с Ибрамом

1После этого Вечный обратился к Ибраму в видении:

– Не бойся, Ибрам. Я – твой щит; награда твоя будет весьма велика.

2Но Ибрам сказал:

– О Владыка Вечный, что Ты можешь мне дать, если я остаюсь бездетным, и моё имущество унаследует Элиезер из Дамаска?

3Ибрам добавил:

– Ты не дал мне детей, и слуга моего дома станет моим наследником.

4В ответ было ему слово Вечного:

– Он не станет твоим наследником; от семени твоего будет тебе наследник.

5Вечный вывел его наружу и сказал:

– Взгляни на небеса и сосчитай звёзды, если можешь их сосчитать.

И сказал ему:

– Так многочисленно будет твоё потомство.

6Ибрам поверил Вечному, и Он вменил ему это в праведность.

7Ещё Он сказал ему:

– Я Вечный, Который вывел тебя из Ура Халдейского, чтобы дать тебе во владение эту землю.

8Но Ибрам спросил:

– О Владыка Вечный, как мне убедиться, что я буду владеть ею?

9Вечный сказал ему:

– Приведи Мне трёхлетнюю телицу, трёхлетнюю козу и трёхлетнего барана, а также принеси горлицу и молодого голубя.

10Ибрам так и сделал. Он рассёк их пополам и разложил половины одну напротив другой; но птиц он не рассёк пополам. 11Хищные птицы слетались на трупы, но Ибрам отгонял их. 12Когда солнце начало садиться, Ибрама охватил глубокий сон; и тут кромешная тьма опустилась, и ужас объял его.

13Вечный сказал ему:

– Знай же, что твои потомки будут странниками в чужой земле; они будут обращены в рабство и будут угнетаемы четыреста лет. 14Но Я накажу народ, поработивший их, и тогда они выйдут оттуда с большим имуществом. 15Ты отойдёшь к отцам своим в мире и будешь погребён в глубокой старости. 16В четвёртом поколении15:16 То есть примерно через 400 лет. твои потомки вернутся сюда, потому что грех аморреев ещё не достиг полной меры.

17Когда солнце село и стало темно, вдруг появились дымящаяся жаровня с пылающим факелом и прошли между рассечёнными кусками. 18В тот день Вечный заключил священное соглашение с Ибрамом и сказал:

– Я отдаю твоим потомкам эту землю, от египетской реки15:18 От египетской реки – существует два толкования: большинство толкователей считают, что это пересыхающая летом река Вади аль-Ариш, граница между Ханааном и Египтом (см. Чис. 34:5; Иеш. 15:4), но другие думают, что речь здесь идёт о реке Нил. до великой реки Евфрат: 19землю кенеев, кенезеев, кедмонеев, 20хеттов, перизеев, рефаитов, 21аморреев, хананеев, гиргашеев и иевусеев.