Àwọn ọmọ àti àwọn òbí
1Ẹ̀yin ọmọ, ẹ máa gbọ́ tí àwọn òbí i yín nínú Olúwa: nítorí pé èyí ní ó tọ́. 26.2: Ek 20.12.“Bọ̀wọ̀ fún baba àti ìyá rẹ,” èyí tí í ṣe òfin kìn-ín-ní pẹ̀lú ìlérí, 36.3: De 5.16.“ki ó lé dára fún ọ, àti kí ìwọ lè wà pẹ́ ní ayé.”
4Àti ẹ̀yin baba, ẹ má ṣe mú àwọn ọmọ yín bínú, ṣùgbọ́n ẹ máa tọ́ wọn nínú ẹ̀kọ́ àti ìkìlọ̀ Olúwa.
Àwọn ẹrú àti olówó wọn
5Ẹ̀yin ọmọ ọ̀dọ̀, ẹ máa gbọ́ ti àwọn olúwa yín nípá ti ara, pẹ̀lú ìbẹ̀rù àti ìwárìrì, nínú òtítọ́ ọkàn yín, bí ẹni pé sí Kristi. 6Gbọ́ ọ̀rọ̀ sí wọn lẹ́nu kì í ṣe láti rí ojúrere wọn nígbà tí ojú wọn bá ń bẹ lára rẹ, ṣùgbọ́n bí ẹrú Kristi, ní ṣíṣe ìfẹ́ Ọlọ́run láti inú ọkàn rẹ. 7Ẹ máa fi gbogbo ọkàn yin ṣe iṣẹ́ ìsìn bí sí Olúwa, kì í sí ṣe sí ènìyàn. 8Bí ẹ̀yin ti mọ̀ pé ohun rere tí olúkúlùkù bá ṣe òun náà ní yóò sí gbà padà lọ́dọ̀ Olúwa, ìbá à ṣe ẹrú, tàbí òmìnira.
9Àti ẹ̀yin ọ̀gá, ẹ máa ṣe irú ìtọ́jú kan náà sí àwọn ẹrú yin, ẹ máa dín ìbẹ̀rù yín kù bí ẹ̀yin ti mọ̀ pé Olúwa ẹ̀yin tìkára yín ń bẹ ní ọ̀run; kò sì ṣí ojúsàájú ènìyàn lọ́dọ̀ rẹ̀.
Ìhámọ́ra Ọlọ́run
10Ní àkótán, ara mí, ẹ jẹ́ alágbára nínú Olúwa, àti nínú agbára ipá rẹ̀. 11Ẹ gbé gbogbo ìhámọ́ra Ọlọ́run wọ̀, kí ẹ̀yin lè kọ ojú ìjà sí àrékérekè èṣù. 12Nítorí pé kì í ṣe ẹ̀jẹ̀ àti ẹran-ara ní àwa ń bá jìjàkadì, ṣùgbọ́n àwọn ìjòyè, àwọn ọlọ́lá, àwọn aláṣẹ ìbí òkùnkùn ayé yìí, àti àwọn ẹ̀mí búburú ní ojú ọ̀run. 13Nítorí náà, ẹ gbé gbogbo ìhámọ́ra Ọlọ́run wọ̀, kí ẹ̀yin lè dúró tiiri sí ọjọ́ ibi, nígbà tí ẹ̀yin bá sì ti ṣe ohun gbogbo tan kí ẹ sì dúró. 146.14: Isa 11.5; 59.17; 1Tẹ 5.8.Ẹ dúró nítorí náà lẹ́yìn tí ẹ fi àmùrè òtítọ́ dì ẹ̀gbẹ́ yin, tí ẹ sì ti di ìgbàyà òdodo mọ́ra. 156.15: Isa 52.7.Tí ẹ sì ti fi ìmúra ìhìnrere àlàáfíà wọ ẹsẹ̀ yín ní bàtà. 16Ní àfikún, ẹ mú apata ìgbàgbọ́, nípa èyí tí ẹ̀yin lè máa fi paná gbogbo ọfà iná ẹni ibi náà. 17Kí ẹ sì mú àṣíborí ìgbàlà, àti idà ẹ̀mí, tí í ṣe ọ̀rọ̀ Ọlọ́run.
18Pẹ̀lú gbogbo àdúrà àti ẹ̀bẹ̀ ni kí ẹ máa gbàdúrà nígbà gbogbo nínú Ẹ̀mí, kí ẹ sì máa ṣọ́ra sí i nínú ìdúró ṣinṣin gbogbo àti ẹ̀bẹ̀ fún gbogbo ènìyàn mímọ́. 19Kí ẹ sì máa gbàdúrà fún mí pẹ̀lú, kí Ọlọ́run lè fún mí ní ọ̀rọ̀ tí ó yẹ kí èmi lè máa fì ìgboyà sọ àwọn ohun ìjìnlẹ̀ ìhìnrere náà. 20Nítorí èyí tí èmí jẹ́ ikọ̀ nínú ẹ̀wọ̀n: kí èmi lè máa fi ìgboyà sọ̀rọ̀ nínú rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ó ti tọ́ fún mí láti máa sọ.
Àwọn ìkíni ìkẹyìn
216.21-22: Kl 4.7-8. Tikiku, arákùnrin olùfẹ́ àti ìránṣẹ́ olóòtítọ́ nínú Olúwa yóò sọ ohun gbogbo dí mí mọ̀ fún yín, kí ẹ̀yin pẹ̀lú lè mọ̀ bí nǹkan ti rí fún mí àti bí mo tí ń ṣe sí. 22Ẹni tí mo rán sí yín nítorí èyí náà, kí ẹ lè mọ̀ bí a tí wà, kì òun lè tu ọkàn yín nínú.
23Àlàáfíà fún àwọn ará, àti ìfẹ́ pẹ̀lú ìgbàgbọ́, láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wà, àti Olúwa wà Jesu Kristi.
24Kí oore-ọ̀fẹ́ wà pẹ̀lú gbogbo àwọn tí ó fẹ́ Olúwa wa Jesu Kristi ni àìṣẹ̀tàn.
فرزندان و والدين
1ای فرزندان، پدر و مادر خود را اطاعت كنيد كه اين كار درستی است، زيرا خداوند اختيار زندگی شما را به دست ايشان سپرده است. 2نخستين حكم از «ده فرمان» كه با وعده همراه میباشد، اينست كه «پدر و مادر خود را احترام نما!» 3و وعدهای كه خدا داده، اينست كه اگر احترام پدر و مادر خود را نگاه داريد، عمری طولانی و با سعادت خواهيد داشت.
4در اينجا سخنی نيز با شما پدر و مادرها دارم: فرزندانتان را بيش از حد سرزنش نكنيد، مبادا دلگير و عصبی شوند. ايشان را آن طور كه خداوند میپسندد، با محبت تربيت كنيد، و از كلام خدا ايشان را پند و نصيحت دهيد.
غلامان و اربابان
5ای غلامان، از اربابتان در اين دنيا با ترس و احترام اطاعت نماييد و ايشان را از صميم قلب خدمت كنيد، با اين تصور كه مسيح را خدمت میكنيد. 6طوری نباشد كه وظايف كاری خود را فقط در حضور ايشان خوب انجام دهيد، و وقتی نيستند شانه خالی كنيد. بلكه همچون خادمين مسيح كه خواست خدا را با جان و دل انجام میدهند، هميشه وظيفه خود را انجام دهيد. 7با عشق و علاقه كار كنيد، درست مانند آنكه برای خداوند كار میكنيد، نه برای انسان. 8فراموش نكنيد كه چه غلام باشيد چه آزاد، برای هر عمل نيكو كه انجام میدهيد، از خداوند پاداش خواهيد گرفت.
9و شما اربابان، با غلامان و زيردستان خود درست رفتار كنيد، همانطور كه به ايشان نيز گفتم كه با شما درست رفتار نمايند. آنان را تهديد نكنيد. فراموش نكنيد كه شما هم غلام هستيد، غلام عيسی مسيح. شما هر دو يک ارباب داريد و او از كسی طرفداری نمیكند.
اسلحهٔ جنگ روحانی
10در خاتمه از شما میخواهم كه از قدرت عظيم خداوند در درون خود، نيرو بگيريد و زورآور شويد! 11خود را با تمام سلاحهای خدا مجهز كنيد تا بتوانيد در برابر وسوسهها و نيرنگهای شيطان ايستادگی نماييد. 12بدانيد كه جنگ ما با انسانها نيست، انسانهايی كه گوشت و خون دارند؛ بلكه ما با موجودات نامرئی میجنگيم كه بر دنيای نامرئی حكومت میكنند، يعنی بر موجودات شيطانی و فرمانروايان شرور تاريكی. بلی، جنگ ما با اينهاست، با لشكرهايی از ارواح شرور كه در دنيای ارواح زندگی میكنند.
13بنابراين، از يکيک سلاحهای خدا به هنگام حمله دشمنتان، شيطان، استفاده كنيد، تا بتوانيد حملههای او را دفع نماييد و در آخر، بر پايهای خود محكم بايستيد.
14اما برای اين منظور، «كمربند محكم راستی» را به كمر ببنديد و «زرهٔ عدالت خدا» را در بر نماييد. 15«كفش انجيل آرامشبخش» را به پا كنيد تا به همه جا رفته، پيغام انجيل را به همه اعلام نماييد. 16«سپر ايمان» را نيز برداريد تا در مقابل تيرهای آتشين شيطان محفوظ بمانيد. 17«كلاهخود نجات» را بر سر بگذاريد و «شمشير روح» را كه همان كلام خداست، به دست گيريد.
18هميشه دعا كنيد! در دعا از خدا آن چيزهايی را بخواهيد كه مطابق خواست روحالقدس است. مسايل و نيازهای خود را به او بگوييد، و برای همهٔ ايمانداران با اشتياق زياد و جديت دعا كنيد. 19برای من نيز دعا كنيد تا وقتی با دليری با ديگران دربارهٔ خداوند سخن گويم و شرح میدهم كه چگونه غيريهوديان نيز میتوانند نجات پيدا كنند، خدا كلمات مناسب را به من بدهد. 20در واقع، به سبب اعلام همين پيغام است كه در زندان به سر میبرم. اما دعا كنيد كه حتی در زندان نيز با شجاعت و آن طور كه بايد، دربارهٔ مسيح سخن بگويم.
سلامهای پايانی
21«تيخيكوس» برادر عزيز ما و خدمتگزار وفادار خداوند، از احوال من و از آنچه میكنم، شما را آگاه خواهد ساخت. 22او را فقط به همين منظور نزد شما میفرستم، تا از چگونگی حال ما باخبر شويد و با شنيدن سخنان او دلگرم و تشويق گرديد.
23دعا میكنم كه خدای پدر و خداوند ما عيسی مسيح، به شما برادران عزيز آرامش و محبت و ايمان عطا كند. 24فيض مسيح نصيب تمام كسانی باشد كه با خلوص نيت، خداوند ما عيسی مسيح را دوست میدارند.