Amosi 1 – YCB & BDS

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Amosi 1:1-15

1Àwọn ọ̀rọ̀ Amosi, ọ̀kan lára àwọn olùṣọ́-àgùntàn Tekoa; ohun tí o rí nípa Israẹli ní ọdún méjì ṣáájú ilẹ̀-rírì, nígbà tí Ussiah ọba Juda àti Jeroboamu ọmọ Jehoaṣi jẹ́ ọba ní ilẹ̀ Israẹli.

21.2: Jl 3.16.Ó wí pé:

Olúwa yóò bú jáde láti Sioni

ohùn rẹ̀ yóò sì sán bí àrá láti Jerusalẹmu wá;

Ibùgbé àwọn olùṣọ́-àgùntàn yóò sì ṣọ̀fọ̀,

orí òkè Karmeli yóò sì rọ.”

Ìdájọ́ àwọn aládùúgbò Israẹli

31.3-5: Isa 17.1-3; Jr 49.23-27; Sk 9.1.Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

“Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ mẹ́ta tí Damasku,

àní fún mẹ́rin, Èmi kò ní yí ìpinnu ìjìyà mi padà

Nítorí wọn fi ohun èlò ìpakà pa Gileadi.

Pẹ̀lú ohun èlò irin tí ó ní eyín mímú

4Èmi yóò rán iná sí ilé Hasaeli

Èyí ti yóò jó àwọn ààfin Beni-Hadadi run.

5Èmi yóò ṣẹ́ ọ̀pá ìdábùú Damasku;

Èmi yóò sì pa ọba tí ó wà ní Àfonífojì Afeni run

àti ẹni tí ó di ọ̀pá aládé mú ní Beti-Edeni.

Àwọn ará a Aramu yóò lọ sí ìgbèkùn sí Kiri,”

ni Olúwa wí.

61.6-8: Isa 14.29-31; Jr 47; El 25.15-17; Jl 3.4-8; Sf 2.4-7; Sk 9.5-7.Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

“Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ mẹ́ta Gasa,

àní nítorí mẹ́rin,

Èmi kò ní yí ìpinnu ìjìyà mi padà

Gẹ́gẹ́ bí í oníṣòwò ẹrú,

ó kó gbogbo àwọn ènìyàn mi ní ìgbèkùn.

Ó sì tà wọ́n fún Edomu,

7Èmi yóò rán iná sí ara odi Gasa

tí yóò jó gbogbo ààfin rẹ̀ run

8Èmi yóò ké àwọn olùgbé Aṣdodu kúrò,

ti ẹni tí ó di ọ̀pá aládé ní Aṣkeloni mú.

Èmi yóò yí ọwọ́ mi sí Ekroni

títí tí ìyókù Filistini yóò fi ṣègbé,”

ni Olúwa Olódùmarè wí.

91.9-10: Isa 23; El 26.1–28.19; Jl 3.4-8; Sk 9.3-4.Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

“Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ mẹ́ta ti Tire

àní nítorí mẹ́rin, Èmi kì yóò yí ìpinnu ìjìyà mi padà.

Nítorí wọ́n ta gbogbo àwọn ènìyàn tí ó wà ní ìgbèkùn fún Edomu

Wọn kò sì nání májẹ̀mú ọbàkan,

10Èmi yóò rán iná sí ara odi Tire

Tí yóò jó gbogbo àwọn ààfin rẹ̀ run.”

111.11-12: Isa 34; 63.1-6; Jr 49.7-22; El 25.12-14; 35; Ọd; Ml 1.2-5.Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

“Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ mẹ́ta tí Edomu,

àní nítorí mẹ́rin, Èmi kò ní yí ìpinnu ìjìyà mi padà

Nítorí òhun fi idà lépa arákùnrin rẹ̀,

Ó sì gbé gbogbo àánú sọnù

ìbínú rẹ̀ sì ń faniya títí

ó sì pa ìbínú rẹ̀ bí èéfín mọ́

12Èmi yóò rán iná sí orí Temani

Tí yóò jó gbogbo ààfin Bosra run.”

131.13-15: Jr 49.1-6; El 21.28-32; 25.1-7; Sf 2.8-11.Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

“Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ mẹ́ta ti Ammoni

àní mẹ́rin, Èmi kò ní yí ìpinnu ìjìyà mi padà,

Nítorí wọn ti la inú àwọn aboyún Gileadi

kí wọ́n ba à lè fẹ ilẹ̀ wọn sẹ́yìn.

14Èmi yóò rán iná sí ara odi Rabba

èyí tí yóò jó àwọn ààfin rẹ̀ run

pẹ̀lú ìhó ayọ̀ ní ọjọ́ ogun,

pẹ̀lú ìjì líle ni ọjọ́ àjà.

15Ọba wọn yóò sì lọ sí ìgbèkùn

Òun àti àwọn ọmọ-aládé rẹ̀ lápapọ̀,”

ni Olúwa wí.

La Bible du Semeur

Amos 1:1-15

1Paroles d’Amos, l’un des éleveurs de Teqoa1.1 A une vingtaine de kilomètres au sud de Jérusalem., qui lui furent révélées au sujet d’Israël1.1 C’est-à-dire le royaume du Nord., au temps d’Ozias, roi de Juda, et au temps de Jéroboam, fils de Joas, roi d’Israël, deux ans avant le tremblement de terre1.1 Sur le règne d’Ozias ou Azaria (792 à 740 av. J.-C.), voir 2 R 15.1-7 ; 2 Ch 26.1-23 ; sur celui de Jéroboam II (793 à 753 av. J.-C.), voir 2 R 14.23-29. On ne sait rien de ce tremblement de terre, sinon qu’il a dû frapper les esprits puisque Zacharie le mentionne encore deux siècles et demi plus tard (Za 14.5).. 2Amos dit :

De Sion, l’Eternel rugit1.2 Voir Jl 4.16.

et, de Jérusalem, ╵il donne de la voix.

Les pâturages des bergers ╵se flétriront.

Le sommet du Carmel ╵se desséchera.

Le jugement approche

Contre les Syriens

3L’Eternel dit ceci :

Damas1.3 Capitale de la Syrie, sur la frontière nord d’Israël. a perpétré ╵de nombreux crimes ;

il a dépassé les limites1.3 Tel est le sens de l’expression hébraïque : à cause de trois crimes de Damas et même de quatre. On trouve une expression identique en 1.6, 9, 11, 13 ; 2.1, 4, 6 (voir Pr 6.16 ; 30.15, 18, 21, 29 ; Mi 5.14).. ╵Voilà pourquoi ╵je ne reviendrai pas ╵sur l’arrêt que j’ai pris,

car ils ont écrasé ╵sous des herses de fer ╵les gens de Galaad1.3 Partie du territoire israélite à l’est du Jourdain..

4Je mettrai donc le feu ╵au palais d’Hazaël1.4 Roi de Syrie de 842 à 796 av. J.-C., fondateur d’une nouvelle dynastie (2 R 8.7-15, 28).,

et il consumera ╵les palais du roi Ben-Hadad1.4 Fils de Hazaël (2 R 13.24), deuxième du nom (voir 2 R 8.14-15), roi de 796 à 775 av. J.-C..

5Oui, je ferai sauter ╵les verrous de Damas,

je ferai disparaître ╵celui qui siège sur le trône1.5 celui qui siège sur le trône. Autre traduction : ceux qui habitent. ╵dans la vallée d’Aven

et celui qui est au pouvoir ╵à Beth-Eden1.5 La vallée d’Aven (c’est-à-dire du Péché) et Beth-Eden (c’est-à-dire la Maison du Plaisir), endroits à la localisation inconnue, sont certainement des noms symboliques ou des sobriquets qui désignent la Syrie et Damas, située dans la vallée de l’Amana (voir 2 R 5.12).,

et les Syriens ╵partiront en exil à Qir1.5 Voir 9.7 et note.,

l’Eternel le déclare.

Contre les Philistins

6L’Eternel dit ceci :

Gaza1.6 Ville de Philistie. a perpétré ╵de nombreux crimes ;

il a dépassé les limites. ╵Voilà pourquoi ╵je ne reviendrai pas ╵sur l’arrêt que j’ai pris,

car ils ont déporté ╵des gens en masse ╵pour les livrer ╵à Edom comme esclaves.

7Je mettrai donc le feu ╵aux remparts de Gaza,

et il consumera ╵les palais qui s’y trouvent.

8Je ferai disparaître ╵celui qui, dans Ashdod, ╵est assis sur le trône1.8 celui qui, dans Ashdod… trône. Autre traduction : les habitants d’Ashdod.,

et celui qui est au pouvoir ╵à Ashkelôn.

Je me tournerai contre Eqrôn

et ainsi périront ╵les derniers Philistins1.8 Ashdod, Ashkelôn et Eqrôn: trois autres villes philistines. Gath, la cinquième (voir 6.2), a sans doute déjà été vaincue par Ozias (2 Ch 26.6)..

Voici ce que déclare ╵le Seigneur, l’Eternel.

Contre les Phéniciens

9L’Eternel dit ceci :

Tyr a commis ╵de nombreux crimes ;

il a dépassé les limites. ╵Voilà pourquoi ╵je ne reviendrai pas ╵sur l’arrêt que j’ai pris,

car ils ont livré à Edom ╵des déportés en masse1.9 Il s’agit d’Israélites livrés par les Phéniciens de Tyr aux Edomites.,

ils n’ont fait aucun cas ╵de l’alliance1.9 Sur les rapports entre les Phéniciens et Israël, voir 2 S 5.11 ; 1 R 5.15-26 ; 9.11-14 ; Jl 4.4-8. ╵qui les liait au peuple frère.

10Je mettrai donc le feu ╵aux murailles de Tyr,

et il consumera ╵les palais qui s’y trouvent.

Contre les Edomites

11L’Eternel dit ceci :

Edom a perpétré ╵de nombreux crimes ;

il a dépassé les limites. ╵Voilà pourquoi ╵je ne reviendrai pas ╵sur l’arrêt que j’ai pris,

car il a poursuivi ╵le peuple frère avec l’épée1.11 Les Edomites, descendants d’Isaac par Esaü (Gn 36), occupant le sud de la mer Morte, ont toujours été ennemis d’Israël (voir Nb 20.14-21 ; Lm 4.21 ; Jl 4.19 ; Ab 11-14 ; Ps 137.7).,

en étouffant toute pitié,

et il n’a pas cessé ╵de le meurtrir avec colère

et de nourrir sans fin ╵sa rage invétérée.

12Je mettrai donc le feu ╵au milieu de Témân,

et il consumera ╵les palais de Botsra1.12 Témân, ville ou région d’Edom, qui représente souvent l’ensemble du pays ; Botsra, ville importante d’Edom..

Contre les Ammonites

13L’Eternel dit ceci :

Les Ammonites1.13 Les Ammonites étaient installés en Transjordanie près de la tribu de Gad. ont perpétré ╵de nombreux crimes ;

ils ont dépassé les limites. ╵Voilà pourquoi ╵je ne reviendrai pas ╵sur l’arrêt que j’ai pris,

parce qu’ils ont ouvert le ventre

des femmes qui étaient enceintes ╵en Galaad,

en recherchant ╵à agrandir leur territoire.

14J’incendierai ╵les remparts de Rabba1.14 Capitale des Ammonites, la ville moderne d’Amman..

Alors le feu consumera ╵les palais qui s’y trouvent,

au bruit des cris de guerre

en un jour de combat,

dans la tempête

en un jour d’ouragan.

15Leur roi s’en ira en exil

avec tous ses ministres,

l’Eternel le déclare.